Pular para o conteúdo
Publicidade

Números 6

Òfin fún àwọn Nasiri

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , ọkùnrin tàbí obìnrin kan jẹ́ ̀jẹ́ pàtàkì, ̀jẹ́ ìyara-ẹni-sọ́tọ̀ Olúwa nípa àìgé irun orí (Nasiri), 3 6.3: Lk 1.15.irú ẹni bẹ́̀ gbọdọ̀ yàgò fún wáìnì tàbí ọtí líle, ọtí wáìnì kíkan àti àwọn ohun mímu mìíràn kan. gbọdọ̀ mu èso àjàrà tàbí ó jẹ èso àjàrà tútù tàbí gbígbẹ. 4 Níwọ́n ìgbà ó jẹ́ Nasiri, gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun a fi èso àjàrà ṣe, ìbá à ṣe kóró tàbí èèpo rẹ̀.

5 " gbogbo ìgbà ̀jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, abẹ kankan ṣe kàn án orí. Ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ títí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ Olúwa yóò fi ; ó gbọdọ̀ jẹ́ irun orí rẹ̀ gùn.

6 " gbogbo àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ Olúwa gbọdọ̀ súnmọ́ òkú ènìyàn. 7 Ìbá à ṣe òkú baba, àti ìyá rẹ̀, ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin tàbí àbúrò rẹ̀, gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí wọn, nítorí àmì ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ Ọlọ́run orí rẹ̀. 8 gbogbo àsìkò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, ó jẹ́ mímọ́ Olúwa.

9 " ẹnìkan ̀dọ̀ rẹ̀ òjijì, ó ba irun rẹ̀ sọ́tọ̀ jẹ́; ó gbọdọ̀ irun rẹ̀ ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ èyí í ṣe ọjọ́ keje. 10 ọjọ́ kẹjọ, yóò àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé méjì sọ́dọ̀ àlùfáà ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 11 Àlùfáà yóò fi ̀kan ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun láti fi ṣe ètùtù fún un nítorí ó ti ṣẹ̀ nípa wíwà níbi òkú ènìyàn . Yóò ya orí rẹ̀ mímọ́ ọjọ́ náà gan an. 12 Ó gbọdọ̀ ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ Olúwa fún àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀, ó gbọdọ̀ akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan gẹ́gẹ́ ọrẹ ̀bi. í ka àwọn ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀ nítorí ó ba ara rẹ̀ jẹ́ àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.

13 6.13-21: Ap 21.24,26. " Èyí ni òfin fún Nasiri nígbà àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ . Wọn ó mu ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 14 Níbẹ̀ ni yóò ti ọrẹ fún Olúwa, akọ ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan àbùkù fún ẹbọ sísun àti ẹgbọrọ-àgùntàn ọlọ́dún kan, àbùkù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, àgbò kan àbùkù fún ọrẹ àlàáfíà, 15 pẹ̀ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu, apẹ̀rẹ̀ àkàrà a fi ìwúkàrà ṣe, àkàrà a fi ìyẹ̀fun dáradára mọ́ òróró àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ a fi òróró sọjọ̀ lórí.

16 " Àlùfáà yóò gbé gbogbo rẹ̀ síwájú Olúwa, yóò ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun. 17 Àlùfáà yóò fi àgbò náà ẹbọ àlàáfíà Olúwa, pẹ̀apẹ̀rẹ̀ àkàrà ìwúkàrà; yóò ẹbọ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu.

18 " Nígbà náà ni Nasiri náà yóò irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. Yóò fi irun náà sínú iná lábẹ́ ẹbọ àlàáfíà.

19 " Lẹ́yìn Nasiri ti irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ tan, àlùfáà yóò apá àgbò bíbọ̀, àkàrà aláìwú kan àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ ìwúkàrà láti inú apẹ̀rẹ̀ yóò gbogbo rẹ̀ e lọ́wọ́. 20 Àlùfáà yóò fi gbogbo rẹ̀ níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì, wọ́n jẹ́ mímọ́, wọ́n jẹ́ ti àlùfáà pẹ̀igẹ̀ a àti itan wọ́n . Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà mu wáìnì.

21 " Èyí ni òfin Nasiri jẹ́ ̀jẹ́, ọrẹ rẹ̀ Olúwa, yóò ìbámu pẹ̀ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ Nasiri, àfikún àwọn ohun mìíràn lágbára láti . Ó gbọdọ̀ ̀jẹ́ jẹ́ ṣe gẹ́gẹ́ òfin Nasiri.’ "

Ìbùkún àlùfáà

22 Olúwa sọ fún Mose , 23 "Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ , Báyìí ni ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. sọ fún wọn ,

24 " ‘ "Olúwa bùkún un yín,

ó pa yín mọ́.

25 Olúwa o ojú rẹ̀ ó mọ́lẹ̀ i yín lára.

ó ṣàánú fún un yín.

26 Olúwa bojú yín,

ó fún un yín àlàáfíà." 

27 "Báyìí ni wọn ó ṣe fi orúkọ mi sára àwọn ọmọ Israẹli, Èmi ó bùkún wọn."

Veja também