7 "Ẹ jẹ́ kí a kọ́ àwọn ìlú wọ̀nyí," ó wí fún Juda, "kí ẹ sì mọ odi yí wọn ká pẹ̀lú àwọn ilé ìṣọ́ gíga, àwọn ẹnu-ọ̀nà òde, àti àwọn ìpẹ́ẹ̀rẹ̀. Ilé náà ti wà, nítorí a ti béèrè lọ́wọ́ Olúwa Ọlọ́run wa; a béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ó sì ti fún wa ní ìsinmi ní gbogbo ọ̀nà." Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kọ́ ọ, wọn sì ṣe rere.
Publicidade
Publicidade