Publicidade

2 Crônicas 19

Jehu Jehoṣafati

1 Nígbà Jehoṣafati ọba Juda padà àlàáfíà ilé rẹ̀ Jerusalẹmu, 2 Jehu aríran, ọmọ Hanani jáde lọ láti lọ pàdé rẹ̀, ó fún ọba , "Ṣé ìwọ yóò máa ran ènìyàn búburú lọ́wọ́, o fẹ́ràn àwọn ó kórìíra Olúwa? Nítorí èyí, ìbínú Olúwa lórí wa. 3 ó ti ó , ohun rere nínú rẹ, nítorí ìwọ ti àwọn ilé àwọn ère òrìṣà Aṣerah kúrò, o múra ọkàn rẹ láti Ọlọ́run."

Jehoṣafati yan àwọn onídàájọ́

4 Jehoṣafati ń gbé Jerusalẹmu ó jáde lọ padà láàrín àwọn ènìyàn láti Beerṣeba òkè ìlú Efraimu, ó wọn padà sọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run baba wọn. 5 Ó yan àwọn onídàájọ́ ilẹ̀ náà, olúkúlùkù ìlú olódi Juda. 6 Ó fun wọ́n , "kíyèsi ohun ̀yin ń ṣe, nítorí ìwọ ṣe ìdájọ́ fun ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa, ẹni ó pẹ̀rẹ ìdájọ́. 7 Nísinsin yìí jẹ́ ìbẹ̀Olúwa ó ọkàn rẹ̀. Ṣe ìdájọ́ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, nítorí pẹ̀Olúwa Ọlọ́run àìṣedéédéé tàbí ojúsàájú tàbí gbígba àbẹ̀tẹ́lẹ̀."

8 Jerusalẹmu pẹ̀, Jehoṣafati yan díẹ̀ lára àwọn Lefi, àwọn àlùfáà àti àwọn olórí ìdílé Israẹli si pípa òfin Olúwa mọ́ àti láti ṣe ìdájọ́. Wọn ń gbé Jerusalẹmu. 9 Ó kìlọ̀ fún wọn . "Ìwọ gbọdọ̀ sìn pẹ̀òtítọ́ àti pẹ̀ọkàn pípé ìbẹ̀Olúwa. 10 gbogbo ẹjọ́ ó níwájú rẹ láti ̀dọ̀ àwọn arákùnrin yín ń gbé ìlú wọn bóyá ̀jẹ̀ ń sàn tàbí ìyókù òfin pẹ̀, pa á láṣẹ ìlànà àti ̀tọ́, ìwọ gbọdọ̀ kìlọ̀ fún wọn láti ṣe dẹ́ṣẹ̀ Olúwa bẹ́̀ kọ́, ìbínú yóò sórí yín, àti sórí àwọn arákùnrin. Ṣe èyí, ìwọ yóò jẹ̀bi.

11 "Amariah àlùfáà ni yóò jẹ́ olórí yín nínú gbogbo ̀ràn ó jẹ́ ti Olúwa, àti Sebadiah ọmọ Iṣmaeli alákòóso ìdílé Juda, yóò jẹ́ olórí gbogbo ̀rọ̀ ọba, àti àwọn ará Lefi pẹ̀yin yóò sìn gẹ́gẹ́ ìjòyè níwájú yín. ṣe é pẹ̀ìmọ́kànle, Olúwa yóò pẹ̀àwọn ń ṣe rere."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-