Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 20

21 Lẹ́yìn ìgbà ó àwọn ènìyàn náà gbèrò tán, Jehoṣafati yàn wọ́n láti kọrin Olúwa àti láti fi ìyìn fún ẹwà ìwà mímọ́ gẹ́gẹ́ ó ń jáde lọ iwájú ogun ńlá náà, ,

"fi ọpẹ́ fún Olúwa,

nítorí àánú rẹ̀ dúró títí láéláé."

22 wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ kọrin àti ìyìn, Olúwa rán ogun ̀yìn àwọn ọkùnrin Ammoni àti Moabu àti òkè Seiri ó ń gbógun ti Juda, wọ́n kọlù wọ́n.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também