Publicidade

Isaías 11

̀ka láti ̀dọ̀ Jese

1 Èèkàn kan yóò sọ láti ibi kùkùté Jese,

láti ara gbòǹgbò rẹ̀ ni ̀ka kan yóò ti so èso.

2 ̀Olúwa yóò e,

̀ọgbọ́n àti ti òye,

̀ìmọ̀ràn àti ti agbára,

̀ìmọ̀ àti ti ìbẹ̀Olúwa.

3 Òun yóò inú dídùn nínú ìbẹ̀Olúwa.

Òun yóò ṣe ìdájọ́ pẹ̀ohun ó fi ojú u rẹ̀ ,

tàbí pẹ̀ohun ó fi etí i rẹ̀ gbọ́,

4 ṣùgbọ́n pẹ̀òdodo ni yóò ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní,

pẹ̀òtítọ́ ni yóò ṣe ìpinnu

fún àwọn aláìní ayé.

Òun yóò lu ayé pẹ̀̀ó ẹnu rẹ̀,

pẹ̀èémí ẹnu rẹ̀ ni yóò pa àwọn ìkà.

5 Òdodo ni yóò jẹ́ ìgbànú rẹ̀

àti òtítọ́ ni yóò ṣe ̀̀gbẹ́ rẹ̀ .

6 Ìkookò yóò máa ọmọ àgùntàn gbé,

ẹkùn yóò sùn ti ewúrẹ́

ọmọ màlúù òun ọmọ kìnnìún

àti ọmọ ẹran ó papọ̀

̀dọ́mọdé yóò máa wọ́n.

7 Màlúù àti beari yóò máa jẹun pọ̀,

àwọn ọmọ wọn yóò dùbúlẹ̀ pọ̀,

kìnnìún yóò máa jẹ koríko

gẹ́gẹ́ akọ màlúù.

8 ̀dọ́mọdé yóò ṣeré lẹ́bàá ihò ọká,

ọmọdé yóò ki ọwọ́ rẹ̀ bọ ìtẹ́ paramọ́lẹ̀.

9 Wọn ṣe ni léṣe tàbí pa ni run

gbogbo òkè mímọ́ mi,

nítorí gbogbo ayé yóò kún fún ìmọ̀ Olúwa

gẹ́gẹ́ omi ti bo Òkun.

10 ọjọ́ náà, gbòǹgbò Jese yóò dúró gẹ́gẹ́ àsíá fún gbogbo ènìyàn, àwọn orílẹ̀-èdè yóò pagbo i , ibùdó ìsinmi rẹ̀ yóò jẹ́ èyí ó lógo. 11 ọjọ́ náà, Olúwa yóò na ọwọ́ rẹ̀ jáde nígbà kejì láti tún gba àwọn ó ṣẹ́àní àwọn a ṣẹ́nínú àwọn ènìyàn an rẹ̀ láti Asiria , láti ìsàlẹ̀ Ejibiti àti òkè Ejibiti, láti Kuṣi, láti Elamu láti Babiloni, láti Hamati àti láti àwọn erékùṣù inú Òkun.

12 Òun yóò gbé àsíá sókè fún àwọn orílẹ̀-èdè,

yóò àwọn ìgbèkùn Israẹli jọ,

yóò gbogbo àwọn ènìyàn Juda a ti fọ́n káàkiri jọ,

láti igun mẹ́rẹ̀̀rin ilẹ̀ ayé.

13 Owú jíjẹ Efraimu yóò pòórá,

àwọn ̀Juda ni a ó kúrò,

Efraimu jowú Juda,

tàbí Juda dojúkọ Efraimu.

14 Wọn yóò mọ́ èjìká Filistini

apá ìwọ̀-oòrùn,

wọn yóò pawọ́pọ̀ kọlu àwọn

ènìyàn apá ìlà-oòrùn.

Wọn yóò gbé ọwọ́ wọn Edomu àti Moabu,

àwọn ará Ammoni yóò di ìwẹ̀wọn.

15 Olúwa yóò sọ di gbígbé

àyasí Òkun Ejibiti,

pẹ̀atẹ́gùn gbígbóná ni yóò na ọwọ́ rẹ̀,

kọjá lórí odò Eufurate.

Òun yóò sọ ́ di ọmọdò méje

fi jẹ́ àwọn ènìyàn

yóò máa á kọjá pẹ̀bàtà.

16 ̀gidi yóò fún àwọn ènìyàn an rẹ̀ ó ṣẹ́

ó sílẹ̀ Asiria,

gẹ́gẹ́ ó ti fún Israẹli

nígbà wọ́n gòkè láti Ejibiti .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-