Publicidade

Isaías 40

Ìtùnú fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run

1 ú nínú, tu ènìyàn mi nínú,

ni Ọlọ́run yín .

2 Sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ fún Jerusalẹmu

o kéde fún un

iṣẹ́ àṣekára rẹ̀ ti parí,

à ti san gbèsè ̀ṣẹ̀ rẹ̀,

ó ti i gbà láti ọwọ́ Olúwa

ìlọ́po méjì fún gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

3 Ohùn ẹni ń kígbe ijù:

"tún ̀Olúwa ṣe,

ṣe òpópó ó tọ́ aginjù fún Ọlọ́run wa.

4 Gbogbo àfonífojì ni a ó gbé sókè,

gbogbo òkè ńlá àti òkè kékeré ni yóò di pẹ̀tẹ́lẹ̀;

wíwọ́ ni a ó sọ di títọ́ àti

̀pálapàla ni a óò sọ di títẹ́pẹrẹsẹ.

5 Ògo Olúwa yóò di mọ̀,

gbogbo ènìyàn lápapọ̀ ni yóò i.

Nítorí ẹnu Olúwa ni ó ti sọ ́."

6 Ohùn kan , "Kígbe sókè."

Èmi sọ , "Igbe ni èmi ó ?"

"Gbogbo ènìyàn dàbí i koríko,

àti gbogbo ògo wọn dàbí ìtànná igbó.

7 Koríko ń rọ ìtànná ń rẹ̀,

nítorí èémí Olúwa ń fẹ́ wọ́n.

Nítòótọ́ koríko ni àwọn ènìyàn.

8 Koríko ń rọ ìtànná ń rẹ̀,

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Ọlọ́run wa dúró títí láé."

9 Ìwọ o ìyìn ayọ̀ Sioni,

lọ orí òkè gíga.

Ìwọ ó ìyìn ayọ̀ Jerusalẹmu,

gbé ohùn rẹ sókè pẹ̀ariwo,

gbé e sókè, ṣe bẹ̀;

sọ fún àwọn ìlú u Juda,

"Ọlọ́run rẹ nìyìí!"

10 ó, Olúwa Olódùmarè náà ń bọ̀ pẹ̀agbára,

apá rẹ̀ ń jẹ ọba fún un.

ó, èrè rẹ̀ pẹ̀rẹ̀,

àti ìdápadà rẹ̀ ń a bọ̀ .

11 Ó ń tọ́ àwọn agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn:

Ó àwọn ̀dọ́-àgùntàn apá rẹ̀.

Ó gbé wọn súnmọ́ oókan àyà rẹ̀;

ó fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ darí àwọn ó .

12 Ta ni ó tiwọn omi nínú kòtò ọwọ́ rẹ̀,

tàbí pẹ̀ìbú ọwọ́ rẹ̀

ó wọn àwọn ̀run?

Ta ni ó ti erùpẹ̀ ilẹ̀ ayé jọ nínú apẹ̀rẹ̀,

tàbí ó wọn àwọn òkè ńlá lórí ìwọ̀n

àti òkè kéékèèké nínú òsùwọ̀n?

13 Ta ni ó ti mọ ọkàn Olúwa,

tàbí ó ti tọ́ ṣọ́gẹ́gẹ́ olùdámọ̀ràn rẹ̀?

14 Ta ni Olúwa ó á lọ́yẹ

àti ta ni ó kọ́ òun ̀ó tọ́?

Ta ni ẹni náà ó kọ́ ọgbọ́n

tàbí ó fi ipa ̀òye hàn án?

15 Nítòótọ́ àwọn orílẹ̀-èdè dàbí i ̀kún omi nínú garawa;

a wọ́n gẹ́gẹ́ eruku lórí ìwọ̀n;

ó wọn àwọn erékùṣù àfi eruku múnúmúnú ni wọ́n.

16 Lebanoni fún pẹpẹ iná,

tàbí àwọn ẹranko rẹ̀ ó fún ẹbọ sísun.

17 Níwájú rẹ̀ ni gbogbo orílẹ̀-èdè dàbí ohun ;

gbogbo wọn ohun wúlò

ohun .

18 Ta ni nígbà náà ìwọ yóò fi Ọlọ́run ?

Ère wo ni ìwọ yóò fi ṣe àkàwé rẹ̀?

19 ti ère, oníṣọ̀ni ó á,

ti alágbẹ̀dẹ wúrà fi wúrà ó

a ṣe ̀wọ̀n ̀sílífà fún un.

20 Ọkùnrin kan ó tálákà ó

irú ọrẹ bẹ́̀ ,

igi le è .

Ó oníṣọ̀ó

láti ṣe àgbékalẹ̀ ère yóò le è ṣubú.

21 Ǹjẹ́ o ì mọ̀

ìwọ ì gbọ́?

A ì sọ fún láti ìbẹ̀rẹ̀ ?

Ìwọ ì mọ láti ìgbà ìpìlẹ̀ ayé?

22 Òun jókòó lórí ìtẹ́ òkè òbírí ilẹ̀ ayé,

àwọn ènìyàn rẹ̀ dàbí i láńtata.

Ó ta àwọn ̀run ìbòrí ìgúnwà,

ó wọ́n jáde gẹ́gẹ́ àgọ́ láti gbé.

23 Ó sọ àwọn ọmọ ọba di asán

àti àwọn aláṣẹ ayé yìí ni ó ti sọ dòfo.

24 Gẹ́rẹ́ a ti gbìn wọ́n,

kété a gbìn wọ́n,

kété wọ́n fi gbòǹgbò múlẹ̀,

bẹ́̀ ni ó fẹ́ atẹ́gùn wọ́n gbogbo wọn gbẹ,

bẹ́ ni ìjì líle gbá wọn lọ gẹ́gẹ́ ìyàngbò.

25 "Ta ni ó fi mi ?

Tàbí ta ni ó mi dọ́gba?" ni Ẹni Mímọ́ .

26 Gbé ojú rẹ sókè o wo àwọn ̀run.

Ta ni ó àwọn wọ̀nyí?

Ẹni ó àkójọpọ̀ àwọn ìràwọ̀ jáde ̀kọ̀̀kan

ó wọ́n orúkọ lọ́kọ̀̀kan.

Nítorí agbára ńlá àti ipá rẹ̀,

̀kan ṣoṣo nínú wọn sọnù.

27 Èéṣe o fi sọ, ìwọ Jakọbu?

Àti o ṣàròyé, ìwọ Israẹli,

"̀mi pamọ́ níwájú Olúwa;

ìṣe mi ni a kọbi ara láti ọwọ́ Ọlọ́run mi"?

28 Ìwọ ì mọ̀?

Ìwọ ì gbọ́?

Olúwa òun ni Ọlọ́run ayérayé,

Ẹlẹ́dàá gbogbo ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé.

Agara yóò da bẹ́̀ ni ṣàárẹ̀,

àti òye rẹ̀ ni ẹnikẹ́ni le ṣe òdínwọ̀n rẹ̀.

29 Ó ń fi agbára fún àwọn aláàárẹ̀

ó fi kún agbára àwọn agara .

30 Àní, ó ń rẹ̀ wọ́n àwọn ̀dọ́, wọ́n ń rẹ̀wẹ̀,

àwọn ̀dọ́mọkùnrin ń kọsẹ̀ wọ́n ṣubú;

31 ṣùgbọ́n àwọn ó gbẹ́kẹ̀Olúwa

yóò sọ agbára wọn di ̀tun.

Wọn yóò fìyẹ́ lókè idì;

wọn yóò sáré àárẹ̀ wọn,

wọn yóò rìn òòyì kọ́ wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-