Publicidade

Isaías 41

Olùrànlọ́wọ́ fún Israẹli

1 "dákẹ́ jẹ́́ níwájú mi ̀yin erékùṣù!

Jẹ́ àwọn orílẹ̀-èdè tún agbára wọn ṣe!

Jẹ́ wọn síwájú wọn sọ̀rọ̀,

jẹ́ a pàdé pọ̀ ibi ìdájọ́.

2 "Ta ni ó ti ru ẹnìkan sókè láti ìlà-oòrùn ,

ó é olódodo iṣẹ́ tirẹ̀?

Ó gbé àwọn orílẹ̀-èdè e lọ́wọ́

ó ṣẹ́gun àwọn ọba níwájú rẹ̀.

Ó sọ wọ́n di erùpẹ̀ pẹ̀idà rẹ̀,

láti ú ìyàngbò pẹ̀ọrun rẹ̀.

3 Ó ń lépa wọn ó ń kọjá àlàáfíà,

ojú ̀ẹsẹ̀ rẹ̀ rìn .

4 Ta ni ó ti ṣe èyí ó ti jẹ́ ó wáyé,

ó ti pe ìran-ìran láti àtètèkọ́ṣe?

Èmi Olúwa pẹ̀ẹni kìn-ín-ní wọn

àti ẹni ó gbẹ̀yìn, Èmi náà ni."

5 Àwọn erékùṣù ti i wọ́n bẹ̀;

ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé wárìrì.

Wọ́n súnmọ́ tòsí wọ́n síwájú;

6 èkínní ran èkejì lọ́wọ́

ó sọ fún arákùnrin rẹ̀ , "Jẹ́ alágbára!"

7 Oníṣọ̀gba alágbẹ̀dẹ wúrà níyànjú,

àti ẹni ó fi òòlù dán

òun lọ́kàn le, àní ẹni ó ń lu owú.

Ó sọ nípa àjópọ̀ náà , "Ó dára."

Ó fi ìṣó kan ère náà mọ́lẹ̀ ó ba à lulẹ̀.

8 "Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ Israẹli, ìránṣẹ́ mi,

Jakọbu, ẹni mo ti yàn,

̀yin ìran Abrahamu, ̀rẹ́ mi,

9 mo láti ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé,

láti kọ̀rọ̀ rẹ̀ ó jìnnà jùlọ ni mo ti ́.

Èmi , Ìwọ ni ìránṣẹ́ mi;

Èmi ti yàn ́ bẹ́̀ ni èmi ì kọ̀ ́ sílẹ̀.

10 Nítorí náà bẹ̀, nítorí èmi pẹ̀rẹ;

ṣe jẹ́ àyà ó ́, nítorí èmi ni Ọlọ́run rẹ.

Èmi yóò fún lókun èmi ó ràn ́ lọ́wọ́.

Èmi ó gbé pẹ̀ọwọ́ ̀tún òdodo mi.

11 "Gbogbo àwọn ó bínú

ni ojú yóò , wọn yóò di ẹlẹ́;

àwọn ń

yóò dàbí asán, wọn yóò ṣègbé.

12 tilẹ̀ jẹ́ ìwọ yóò àwọn ̀rẹ,

ìwọ yóò wọn.

Gbogbo àwọn ó gbóguntì ́

yóò dàbí ohun .

13 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ó di ọwọ́ ̀tún rẹ

ó sọ fún , ṣe bẹ̀;

Èmi yóò ràn ́ lọ́wọ́.

14 ṣe bẹ̀, ìwọ Jakọbu kòkòrò,

ìwọ Israẹli kékeré,

nítorí Èmi fúnra mi yóò ràn ́ lọ́wọ́,"

ni Olúwa ,

olùdáǹdè rẹ, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.

15 "Kíyèsi, Èmi yóò sọ ́ di òòlù ìpakà tuntun,

ó ti eyín rẹ̀ , ìwọ yóò lu àwọn òkè ńlá,

ìwọ yóò fọ́ wọn túútúú,

a ó sọ òkè kékeré di ìyàngbò.

16 Ìwọ yóò fẹ́ wọn, afẹ́fẹ́ yóò gbá wọn ,

àti ̀fúùfù yóò fẹ́ wọn dànù.

Ṣùgbọ́n ìwọ yóò yọ̀ nínú Olúwa

ìwọ yóò ṣògo nínú Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.

17 "Àwọn tálákà àti aláìní omi,

ṣùgbọ́n ;

ahọ́n wọn gbẹ fún òǹgbẹ.

Ṣùgbọ́n Èmi Olúwa yóò wọn lóhùn;

Èmi, Ọlọ́run Israẹli, yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.

18 Èmi yóò odò ó sàn ibi gíga

àti orísun omi àárín àfonífojì.

Èmi yóò sọ aṣálẹ̀ di adágún omi,

àti ilẹ̀ ó gbẹ gidigidi di orísun omi.

19 Èmi yóò fi sínú aṣálẹ̀

igi kedari àti kasia, maritili àti olifi.

Èmi yóò gbin junifa inú aginjù,

igi firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀

20 bẹ́̀ àwọn ènìyàn yóò fi i wọn yóò fi mọ̀,

wọn ṣàkíyèsí ó wọn,

ọwọ́ Olúwa ni ó ti ṣe èyí,

àti , Ẹni Mímọ́ Israẹli ni ó ti èyí.

21 "ẹjọ́ ," ni Olúwa .

"Tẹ́ àwọn àwíjàre rẹ sílẹ̀," ni ọba Jakọbu ,

22 "àwọn ère òrìṣà rẹ wọlé láti sọ fún wa

ohun yóò ṣẹlẹ̀.

Sọ fún wa ohun àwọn nǹkan àtijọ́ jẹ́,

àwa ṣe àgbéyẹ̀wọn

àwa mọ àbájáde wọn ìparí.

Tàbí o sọ fún wa ohun ó ń bọ̀ ,

23 sọ fún wa ohun ti ọjọ́ iwájú dání

àwa ó mọ̀ ọlọ́run ni yín.

ṣe nǹkan kan, ìbá à ṣe rere tàbí búburú,

bẹ́̀ àyà yóò fi ̀yóò fi kún inú wa.

24 Ṣùgbọ́n ̀yìn ko jásí nǹkan kan

iṣẹ́ yín ni wúlò fún ohunkóhun;

ẹni ó yàn yín jẹ́ ẹni ìríra.

25 "Èmi ti ru ẹnìkan sókè láti àríwá, òun ń bọ

ẹnìkan láti ìlà-oòrùn ó pe orúkọ mi.

Òun gun àwọn aláṣẹ mọ́lẹ̀ ẹni odò ni wọ́n,

àfi ẹni amọ̀kòkò ti ń gún amọ̀.

26 Ta ni ó sọ èyí láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, àwa fi mọ̀,

tàbí ṣáájú àkókò, àwa fi , Òun sọ òtítọ́’?

Ẹnikẹ́ni sọ nípa èyí,

ẹnikẹ́ni sàsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀,

ẹnikẹ́ni gbọ́ ̀rọ̀ kan láti ̀dọ̀ rẹ̀.

27 Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ ó sọ fún Sioni , ó, àwọn nìyìí!

Mo fún Jerusalẹmu ìránṣẹ́ ìrò ìròyìn ayọ̀ kan.

28 Èmi , ṣùgbọ́n ẹnìkan

ẹnìkan nínú wọn ó ìmọ̀ràn ,

ẹnìkan ó dáhùn nígbà mo bi wọ́n.

29 Kíyèsi i, irọ́ ni gbogbo wọn!

Gbogbo ìṣe wọn jásí asán;

àwọn ère wọn ṣé fún afẹ́fẹ́ àti dàrúdàpọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-