Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaías 8

Isaiah àti ọmọ rẹ jẹ àmì

1 Olúwa sọ fún mi , ìwé ńlá kan, o fi kálàmù ìkọ̀lásán kọ Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi. 2 Èmi yóò Uriah àlùfáà àti Sekariah ọmọ Jeberekiah gẹ́gẹ́ ẹlẹ́rìí òtítọ́ ̀dọ̀ mi.

3 Lẹ́yìn náà, mo lọ ̀dọ̀ wòlíì obìnrin náà, ó lóyún, ó ọmọkùnrin kan. Olúwa fún mi , "Pe orúkọ rẹ̀ Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi. 4 ọmọkùnrin náà mọ a ti ń sọ , Baba mitàbí Ìyá mi,gbogbo ọrọ̀ Damasku àti ìkógun ti Samaria ni ọba àwọn Asiria yóò ti lọ."

5 Olúwa tún sọ fún mi ,

6 "Nítorí àwọn ènìyàn yìí ti kọ

omi Ṣiloa ń sàn jẹ́́jẹ́ sílẹ̀

wọ́n ń yọ̀ nínú Resini

àti ọmọ Remaliah,

7 ǹjẹ́ nítorí náà kíyèsi i, Olúwa ń fa omi odò ó le,

ó pọ̀ sórí wọn,

àní, ọba Asiria àti gbogbo ògo rẹ̀,

yóò sórí gbogbo ̀odò rẹ̀,

yóò gun orí gbogbo bèbè rẹ̀,

8 yóò gbá àárín Juda kọjá,

yóò ṣàn ó mọ́lẹ̀, yóò un dọ́rùn.

Nínà ìyẹ́ apá rẹ̀ yóò bo gbogbo ìbú ilẹ̀ rẹ̀,

ìwọ Emmanueli."

9 ariwo ogun, ̀yin orílẹ̀-èdè, a fọ́ yín túútúú,

fetísílẹ̀, ̀yin ilẹ̀ jíjìn réré.

palẹ̀mọ́ fún ogun, a fọ́ túútúú!

10 gbìmọ̀ pọ̀, yóò di asán,

gbèrò ̀rọ̀ náà, ṣùgbọ́n yóò dúró,

nítorí Ọlọ́run pẹ̀wa.

Bẹ̀Ọlọ́run

11 Olúwa mi sọ̀rọ̀ pẹ̀ọwọ́ agbára rẹ̀ o ìkìlọ̀ fún mi , èmi gbọdọ̀ tẹ̀̀àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Ó ,

12 8.12-13: 1Pt 3.14-15. "ṣe pe èyí ̀tẹ̀

gbogbo ohun àwọn ènìyàn yìí ̀tẹ̀,

ṣe bẹ̀ohun wọ́n bẹ̀,

ṣe fòyà rẹ̀.

13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ẹni ìwọ yóò mímọ́,

Òun ni o bẹ̀

Òun ni àyà rẹ̀ ́,

14 8.14: Ro 9.32-33; 1Pt 2.8. Òun yóò jẹ́ ibi mímọ́

ṣùgbọ́n fún ilé Israẹli méjèèjì ni yóò jẹ́, òkúta í ni kọsẹ̀

àti àpáta ó wọn ṣubú

àti fún àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ni yóò jẹ́ tàkúté àti ìdẹ̀kùn.

15 ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni yóò kọsẹ̀,

wọn yóò ṣubú wọn yóò fọ́ yángá,

okùn yóò wọn, ọwọ́ yóò tẹ̀ wọ́n."

16 Di májẹ̀náà

o fi èdìdì di òfin náà láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi.

17 8.17-18: Hb 2.13. Èmi yóò dúró de Olúwa,

ẹni ó ń fi ojú rẹ̀ pamọ́ fún ilé Jakọbu.

Mo fi ìgbẹ́kẹ̀mi sínú rẹ.

18 Èmi nìyí, àti àwọn ọmọ Olúwa fi fún mi. Àwa jẹ́ àmì àti àpẹẹrẹ Israẹli láti ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni ó ń gbé òkè Sioni.

19 Nígbà àwọn ènìyàn sọ fún un yín lọ ̀dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ àti àwọn oṣó, ti máa ń kún wọ́n ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ǹjẹ́ ha yẹ àwọn ènìyàn béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run wọn ? Èéṣe fi ń òkú sọ̀rọ̀ orúkọ alààyè? 20 òfin àti májẹ̀! wọn sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ yìí, wọn ìmọ́lẹ̀ ọjọ́. 21 Nínú ìnilára àti ebi, ni wọn yóò máa kọjá lọ láàrín ilẹ̀ náà, nígbà ebi pa wọ́n, nígbà yìí ni wọn yóò máa kanra, wọn yóò wòkè, wọn yóò fi ọba àti Ọlọ́run wọn . 22 Nígbà náà ni wọn yóò wolẹ̀, wọn yóò ìpọ́njú, òkùnkùn àti ìpòrúru ó ba ni lẹ́, a ó sọ wọ́n sínú òkùnkùn biribiri.

Veja também