Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Crônicas 13

Abijah ọba Juda

1 13.1,2: 1Ọb 15.1,2,7. ọdún kejìdínlógún ìjọba Jeroboamu, Abijah di ọba Juda. 2 Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Mikaiah, ọmọbìnrin Urieli ti Gibeah.

Ogun láàrín Abijah àti Jeroboamu. 3 Abijah lọ ojú ogun pẹ̀àwọn ọmọ-ogun ogún ̀kẹ́ (400,000) ọkùnrin alágbára, Jeroboamu ogun jọ pẹ̀ogójì ̀kẹ́ (800,000) ̀wọ́ ogun ó lágbára.

4 Abijah dúró lórí òkè Semaraimu òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, ó , Jeroboamu àti gbogbo Israẹli, gbọ́ mi! 5 Ṣé ̀yin mọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli ti fún Dafidi àti àwọn àtẹ̀rẹ̀ ni oyè ọba títí láé nípasẹ̀ májẹ̀iyọ̀? 6 Síbẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, oníṣẹ́ Solomoni ọmọ Dafidi, ṣọ̀tẹ̀ ̀rẹ̀. 7 Àwọn ènìyàn lásán ara wọn jọ ̀dọ̀ rẹ̀, àwọn ọmọ ẹni búburú, wọ́n kẹ̀yìn Rehoboamu ọmọ Solomoni ìgbà ó kéré pinnu fúnra rẹ̀, lágbára láti takò wọ́n.

8 "Nísinsin yìí, ìwọ ṣètò láti kọ́ ìjọba Olúwa, ó lọ́wọ́ àwọn àtẹ̀Dafidi. Ìwọ jẹ́ ọmọ-ogun ó gbilẹ̀, ìwọ pẹ̀rẹ ẹgbọrọ màlúù wúrà ti Jeroboamu láti fi ṣe Ọlọ́run yín. 9 Ṣùgbọ́n ṣé ìwọ àwọn àlùfáà Olúwa jáde, àwọn ọmọ Aaroni àti àwọn ará Lefi. ó ṣe àwọn àlùfáà ti ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn ilẹ̀ mìíràn ti ṣe? Ẹnikẹ́ni ó láti ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ pẹ̀̀dọ́ akọ màlúù àti àgbò méjì jẹ́ àlùfáà ohun í ṣe Ọlọ́run.

10 "ti àwa, Olúwa ni Ọlọ́run wa, àwa ti ì kọ̀ ́ sílẹ̀. Àwọn àlùfáà ó ń sin Olúwa jẹ́ àwọn ọmọ Aaroni àwọn ará Lefi ń ràn wọ́n lọ́wọ́. 11 àràárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́, wọ́n gbé ẹbọ sísun àti tùràrí olóòórùn dídùn síwájú Olúwa. Wọ́n gbé àkàrà jáde sórí tábìlì àsè mímọ́, wọ́n tan iná àwọn fìtílà lórí ìdúró ̀fìtílà wúrà gbogbo ìrọ̀lẹ́. A ń pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa mọ́. Ṣùgbọ́n ìwọ ti kọ̀ ́ sílẹ̀. 12 Ọlọ́run pẹ̀wa; òun ni olórí wa. Àwọn àlùfáà rẹ̀ pẹ̀fèrè wọn yóò fọn ìpè ogun i yín. Ẹyin ọkùnrin Israẹli, ṣe dojú ìjà kọ Olúwa Ọlọ́run baba yín nítorí ̀yin yóò yege."

13 Nísinsin yìí, Jeroboamu ti rán àwọn ̀wọ́ ogun lọ yíká láti jagun ̀yìn. ó jẹ́ , òun níwájú Juda, bíba bùba á ̀yìn wọn. 14 Nígbà Juda bojú wo ̀yìn, kíyèsi i, ogun ń bẹ níwájú àti lẹ́yìn, wọn pe Olúwa, àwọn àlùfáà fun ìpè. 15 Olúkúlùkù, ọkùnrin Juda fún ìpè ogun, ó ṣe, àwọn ọkùnrin Juda ti fun ìpè ogun, ni Ọlọ́run kọlu Jeroboamu àti gbogbo Israẹli níwájú Abijah àti Juda. 16 Àwọn ọmọ Israẹli sálọ kúrò níwájú Juda, Ọlọ́run fi wọ́n wọn lọ́wọ́. 17 Abijah àti àwọn arákùnrin rẹ̀ fi ìdààmú ńlá jẹ wọ́n ìyà, bẹ́̀ ni ̀kẹ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n (500,000) ọkùnrin a yàn ṣubú pípa nínú Israẹli. 18 Báyìí ni a rẹ àwọn ọmọ Israẹli sílẹ̀ àkókò náà, àwọn ọmọ Juda borí nítorí wọ́n gbẹ́kẹ̀Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn.

19 Abijah lépa Jeroboamu, ó gba ìlú lọ́wọ́ rẹ̀, Beteli pẹ̀àwọn ìlú rẹ̀, àti Jeṣana pẹ̀àwọn ìlú rẹ̀, àti Efroni pẹ̀àwọn ìlú rẹ̀. 20 Bẹ́̀ Jeroboamu tún agbára mọ́ ọjọ́ Abijah. Olúwa ú ó .

21 Abijah di alágbára, ó gbé obìnrin mẹ́tàlá ìyàwó, ó bi ọmọkùnrin méjìlélógún, àti ọmọbìnrin mẹ́rìndínlógún.

22 Àti ìyókù ìṣe Abijah, àti ìwà rẹ̀, àti iṣẹ́ rẹ̀, a kọ wọ́n sínú ìwé ìtumọ̀, wòlíì Iddo.

Veja também