Publicidade

2 Crônicas 14

Asa ọba Juda

1 Abijah sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín ìlú Dafidi. Asa ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀. àwọn ọjọ́ rẹ̀, orílẹ̀-èdè àlàáfíà fún ọdún mẹ́wàá.

2 Asa ṣe ohun ó dára, ó tọ́ ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. 3 Ó gbé àwọn pẹpẹ àjèjì kúrò àti àwọn ibi gíga. Ó fọ́ àwọn òkúta a sọ́tọ̀, ó àwọn ère Aṣerah bolẹ̀. 4 Ó pa á láṣẹ fún Juda láti Olúwa Ọlọ́run àwọn baba a wọn àti láti tẹ̀àwọn òfin rẹ̀ àti àṣẹ. 5 Ó gbé àwọn ibi gíga kúrò àti àwọn pẹpẹ tùràrí gbogbo ìlú Juda. Ìjọba àlàáfíà abẹ́ rẹ̀. 6 Ó mọ àwọn ìlú ààbò ti Juda, níwọ̀n ìgbà ìlú ti àlàáfíà. ẹnikẹ́ni ti o jagun pẹ̀rẹ̀ nígbà náà, nítorí Olúwa fún un ìsinmi.

7 "jẹ́ a kọ́ àwọn ìlú wọ̀nyí," ó fún Juda, "mọ odi wọn pẹ̀àwọn ilé ìṣọ́ gíga, àwọn ẹnu-ọ̀òde, àti àwọn ìpẹ́̀rẹ̀. Ilé náà ti , nítorí a ti béèrè lọ́wọ́ Olúwa Ọlọ́run wa; a béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ó ti fún wa ìsinmi gbogbo ̀." Bẹ́̀ ni wọ́n kọ́ , wọn ṣe rere.

8 Asa àwọn ọmọ-ogun ti ó jẹ́ ̀kẹ́ mẹ́̀́dógún (300,000) àwọn ọkùnrin láti Juda. Pẹ̀àwọn ohun èlò àwọn àpáta ńlá àti ̀kọ̀ àti ̀kẹ́ mẹ́rìnlá (280,000) láti Benjamini wọ́n dira pẹ̀àwọn àpáta kéékèèké àti àwọn ọrun. Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ ògbójú jagunjagun ọkùnrin.

9 Sera ará Etiopia yàn láti dojúkọ wọ́n, pẹ̀̀pọ̀ ọmọ-ogun pẹ̀̀́dúnrún (300) kẹ̀kẹ́, wọ́n láti jìnnà réré Meraṣa. 10 Asa jáde lọ láti lọ a. Wọ́n ibi ogun pẹ̀tẹ́lẹ̀ Sefata lẹ́bàá Meraṣa.

11 Nígbà náà, Asa pe Olúwa Ọlọ́run baba a rẹ̀, ó "Olúwa ẹnìkan rẹ láti rán aláìlágbára lọ́wọ́ láti dójú kọ alágbára. Ràn lọ́wọ́, Olúwa Ọlọ́run wa, nítorí àwa gbẹ́kẹ̀àti orúkọ rẹ ni àwa fi láti dojúkọ àwọn ̀pọ̀ ọmọ-ogun yìí. Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run wa; ṣe jẹ́ ènìyàn ṣẹ́gun rẹ."

12 Olúwa lu àwọn ará Kuṣi bolẹ̀ níwájú Asa àti Juda. Àwọn ará Kuṣi sálọ. 13 Asa àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ tẹ̀wọn jìnnà réré Gerari. ̀pọ̀lọpọ̀, àwọn ará Kuṣi ṣubú, wọn le sán padà mọ́. Wọn rún wọn mọ́lẹ̀ níwájú Olúwa àti ọmọ-ogun rẹ̀. Àwọn ọkùnrin Juda ̀pọ̀lọpọ̀ ìkógun. 14 Wọ́n pa gbogbo àwọn ìletò ó ̀Gerari, nítorí ìpayà Olúwa ti sọ̀kalẹ̀ sórí wọn. Wọ́n gbogbo ìkógun àwọn ìletò yìí lọ, níwọ̀n ìgbà ̀pọ̀ ìkógun ti níbẹ̀. 15 Wọ́n kọlu àwọn ibùdó àwọn darandaran, wọ́n gbé àwọn ̀wọ́ ẹran àgùntàn àti àwọn ewúrẹ́ àti àwọn ìbákasẹ. Nígbà náà wọ́n padà Jerusalẹmu.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-