Publicidade

Isaías 26

Orin ìyìn kan

1 ọjọ́ náà ni a ó kọ orin yìí ilẹ̀ Juda.

Àwa ìlú alágbára kan,

Ọlọ́run fi ìgbàlà ṣe

ògiri àti ààbò rẹ̀.

2 Ṣí àwọn ìlẹ̀kùn

àwọn olódodo orílẹ̀-èdè ó wọlé,

orílẹ̀-èdè ó pa ìgbàgbọ́ mọ́.

3 Ìwọ yóò pa á mọ́ àlàáfíà pípé

ọkàn ẹni ó dúró ṣinṣin,

nítorí ó gbẹ́kẹ̀.

4 Gbẹ́kẹ̀Olúwa títí láé,

nítorí Olúwa, Olúwa ni àpáta ayérayé náà.

5 Ó sọ àwọn ó ń gbé òkè di onírẹ̀lẹ̀

ó rẹ ìlú agbéraga náà nílẹ̀;

ó sọ ́ di ilẹ̀ pẹrẹsẹ

ó sọ ́ sílẹ̀ nínú erùpẹ̀.

6 Ẹsẹ̀ tẹ̀ ́ mọ́lẹ̀

ẹsẹ̀ aninilára n ,

ipasẹ̀ àwọn òtòṣì.

7 Ipa ̀àwọn olódodo tẹ́,

ìwọ dúró ṣinṣin, ìwọ ̀

àwọn olódodo ṣe geere.

8 Bẹ́̀ ni, Olúwa, rírìn ̀òfin rẹ

àwa dúró ́;

orúkọ rẹ àti òkìkí rẹ

àwọn ni ohun ọkàn wa ń fẹ́.

9 Ọkàn mi ń pòùngbẹẹ̀ rẹ ̀gànjọ́ òru;

òwúrọ̀ ni ̀mi ń ṣàfẹ́rẹ.

Nígbà ìdájọ́ rẹ sọ̀kalẹ̀ sórí ayé

àwọn ènìyàn yóò kọ́ ìṣòdodo.

10 ó tilẹ̀ jẹ́ a fi oore-ọ̀fẹ́ hàn àwọn ìkà

wọn kọ́ láti sọ òdodo;

kódà ilẹ̀ àwọn ó dúró ṣinṣin wọ́n

tẹ̀síwájú láti máa ṣe ibi

wọn ka ọláńlá Olúwa .

11 Olúwa, ti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè

ṣùgbọ́n àwọn i.

Jẹ́ wọ́n ìtara rẹ fún àwọn ènìyàn rẹ

ojú ó wọ́n;

jẹ́ iná a fi pamọ́ fún àwọn

̀rẹ wọn run.

12 Olúwa, ìwọ fi àlàáfíà lélẹ̀ fún wa;

ohun gbogbo a ti ṣe yọrí ìwọ ni

ó ṣe é fún wa.

13 Olúwa Ọlọ́run wa, àwọn olúwa mìíràn

lẹ́yìn rẹ ti jẹ ọba wa lórí,

ṣùgbọ́n orúkọ rẹ nìkan ni àwa fi ̀wọ̀ fún.

14 Wọ́n ti báyìí, wọn ò láààyè mọ́;

gbogbo ̀ó ti kọjá lọ wọ̀nyí le dìde mọ́.

Ìwọ jẹ́ wọ́n ìyà o sọ wọ́n di asán,

ìwọ pa gbogbo ìrántí wọn rẹ́ pátápátá.

15 Ìwọ ti orílẹ̀-èdè gbòòrò, Olúwa;

ìwọ ti orílẹ̀-èdè i.

Ìwọ ti gba ògo fún ara rẹ;

ìwọ ti sún gbogbo àwọn ààlà ilẹ̀ sẹ́yìn.

16 Olúwa, wọ́n sọ́dọ̀ rẹ nínú ìpọ́njú wọn;

nígbà ìbáwí rẹ lára wọn,

wọ́n gbàdúrà kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́.

17 Gẹ́gẹ́ obìnrin ó lóyún ó fẹ́rẹ̀ bímọ

í rúnra ó ń sọkún nínú ìrora rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni àwa níwájú rẹ Olúwa.

18 Àwa nínú oyún, a nínú ìrora,

ṣùgbọ́n, afẹ́fẹ́ ni a lọ́mọ.

Àwa ìgbàlà ilẹ̀ ayé;

àwa kọ́ ni a àwọn ènìyàn ó láyé.

19 Ṣùgbọ́n àwọn òkú yín yóò láààyè

ara wọn yóò dìde.

Ìwọ o nínú erùpẹ̀,

dìde nílẹ̀ o igbe ayọ̀.

Ìrì rẹ dàbí ìrì òwúrọ̀,

ayé yóò àwọn òkú rẹ̀ lọ́mọ.

20 lọ, ̀yin ènìyàn mi, wọ ìyẹ̀yín lọ

ti àwọn ìlẹ̀kùn lẹ́yìn yín,

fi ara yín pamọ́ fún ìgbà díẹ̀

títí ìbínú rẹ̀ yóò fi rékọjá.

21 Kíyèsi i, Olúwa ń jáde bọ̀ láti ibùgbé rẹ̀

láti jẹ àwọn ènìyàn ilẹ̀ ayé ìyà fún ̀ṣẹ̀ wọn.

Ayé yóò sọ àwọn ̀jẹ̀ a ta orí rẹ̀;

yóò fi àwọn a ti pa pamọ́ mọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-