Publicidade

Isaías 29

Ègbé ni fún ìlú Dafidi

1 Ègbé ni fún , Arieli, Arieli,

ìlú níbi Dafidi tẹ̀!

Fi ọdún kún ọdún

jẹ́ àwọn àkọlùkọgbà àjọ̀dún un rẹ tẹ̀síwájú.

2 Síbẹ̀síbẹ̀ èmi yóò ti Arieli

òun yóò ṣọ̀fọ̀ yóò sọkún,

òun yóò dàbí pẹpẹ ọkàn mi.

3 Èmi yóò bùba níbi gbogbo,

Èmi yóò fi ilé ìṣọ́ ,

Èmi yóò fi iṣẹ́ ìdó ti ni mi dojúkọ ́.

4 ìrẹ̀sílẹ̀, ìwọ ó máa sọ̀rọ̀ láti ilẹ̀ ;

̀rọ̀ rẹ yóò máa kùn jáde láti inú erùpẹ̀.

Ohun rẹ yóò máa jáde i ti ẹnìkan ̀àfọ̀ṣẹ láti ilẹ̀ jáde ,

láti inú erùpẹ̀ ni ohùn rẹ

yóò máa wúyẹ́wúyẹ́.

5 Ṣùgbọ́n àwọn ̀rẹ, yóò dàbí yanrìn kíkúnná,

agbo àwọn aláìláàánú ìyàngbò a fẹ́ dànù.

Lójijì, ìṣẹ́kan,

6 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò

pẹ̀àrá àti ilẹ̀-rírì àti ariwo ńlá,

àti ̀fúùfù líle àti iná ajónirun.

7 Lẹ́yìn náà,

̀gọ̀̀rọ̀ ènìyàn gbogbo orílẹ̀-èdè ó Arieli ,

ó dojú ìjà kọ òun àti ilé olódi rẹ̀

ó í,

yóò dàbí ẹni nínú àlá,

ìran òru

8 àti ìgbà ẹni ebi ń pa ń àlá òun ń jẹun,

ṣùgbọ́n ó , ebi rẹ̀ pẹ̀rẹ̀;

tàbí ìgbà ẹni òǹgbẹ ń gbẹ àlá òun ń mu omi,

ṣùgbọ́n nígbà ó , ó, ó dákú, òǹgbẹ ń gbẹ ọkàn rẹ̀.

Bẹ́̀ ni yóò fún ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè

ń òkè Sioni .

9 bẹ̀ẹnu ó yín,

fọ́ ara yín lójú ríran;

mutí í ṣe ọtí wáìnì,

ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n, ṣùgbọ́n í ṣe ti ọtí líle.

10 Olúwa ti oorun ìjìká sórí i yín:

ó ti yín lójú ̀yin wòlíì;

ó ti bo orí yín ̀yin aríran.

11 Fún un yín gbogbo ìran yìí yàtọ̀ àwọn ̀rọ̀ a fi èdìdì sínú ìwé kíká. fún ẹni ó ka ìwé kíká náà, sọ fún un , "Jọ̀wọ́ ka èyí," òun yóò dáhùn , "Èmi á; a ti í èdìdì." 12 Tàbí fún ẹni ka ìwé kíká náà sọ , "Jọ̀wọ́ ka èyí," òun yóò dáhùn , "Èmi mọ̀ ́n ."

13 Olúwa :

"Àwọn ènìyàn yìí súnmọ́ ̀dọ̀ mi pẹ̀ẹnu wọn,

wọ́n bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀ètè wọn,

ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnnà mi.

Ìsìn wọn si mi

ni a gbé ka orí òfin àwọn

ọkùnrin kọ́ ni.

14 Nítorí náà lẹ́̀kan i èmi yóò ya

àwọn ènìyàn yìí lẹ́nu

pẹ̀ìyanu lórí ìyanu;

ọgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n ni yóò ṣègbé,

ìmọ̀ àwọn onímọ̀ ni yóò pòórá."

15 Ègbé ni fún àwọn ó lọ ̀gbun

láti fi ètò wọn pamọ́ kúrò lójú Olúwa,

wọ́n ń ṣe iṣẹ́ wọn nínú òkùnkùn

wọ́n ,

"Ta wa? Ta ni yóò mọ̀?"

16 ̀yin dojú nǹkan délẹ̀,

ẹni wọ́n amọ̀kòkò dàbí amọ̀!

Ǹjẹ́ ohun a ṣe le sọ fún olùṣe ,

"Òun kọ́ ṣe "?

Ǹjẹ́ ìkòkò sọ nípa amọ̀kòkò ,

"mọ nǹkan"?

17 àìpẹ́ jọjọ, ǹjẹ́

a sọ Lebanoni di pápá ẹlẹ́lójú

àti pápá ẹlẹ́lójú yóò dàbí aginjù?

18 ọjọ́ náà adití yóò gbọ́ ̀rọ̀ ìwé kíká náà,

láti inú fìrífìrí àti òkùnkùn

ni àwọn ojú afọ́yóò ríran.

19 Lẹ́̀kan i àwọn onírẹ̀lẹ̀ yóò yọ̀ nínú Olúwa:

àwọn aláìní yóò yọ̀ nínú Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.

20 Aláìláàánú yóò pòórá,

àwọn ń ṣẹlẹ́yóò di àwátì,

gbogbo àwọn ó ojú ibi ni a ó lulẹ̀—

21 àwọn wọ́n fi ̀rọ̀ kan ẹnìkan di ẹlẹ́bi,

ẹni ń dẹkùn olùgbèjà ilé ẹjọ́

fi ̀èké dun aláìṣẹ̀ ìdájọ́.

22 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa, ẹni ó ra Abrahamu padà sọ ilé Jakọbu:

"Ojú yóò ti Jakọbu mọ́;

ojú wọn yóò rẹ̀wẹ̀mọ́.

23 Nígbà wọ́n i láàrín àwọn ọmọ wọn,

àwọn iṣẹ́ ọwọ́ mi,

wọn yóò ya orúkọ mi mímọ́,

wọn yóò tẹ́wọ́gbà mímọ́ Ẹni Mímọ́ Jakọbu

wọn yóò dìde dúró ìbọ̀wọ̀ fún Ọlọ́run Israẹli.

24 Gbogbo àwọn ń rìn ségesège yóò jèrè ìmọ̀;

gbogbo àwọn ń ṣe àròyé yóò gba ìtọ́sọ́."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-