Publicidade

Isaías 45

1 "Èyí ni ohun Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀,

Kirusi, ọwọ́ ̀tún ẹni mo

láti dojú àwọn orílẹ̀-èdè bolẹ̀ níwájú rẹ̀

àti láti gba ohun ìjà àwọn ọba lọ́wọ́ wọn,

láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀

ó fi jẹ́ a yóò ti àwọn ẹnu-ọ̀.

2 Èmi yóò lọ síwájú rẹ,

Èmi ó tẹ́ àwọn òkè ńlá pẹrẹsẹ

Èmi yóò fọ gbogbo ẹnu-ọ̀idẹ

èmi ó ̀irin.

3 Èmi yóò fún àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn,

ọrọ̀ a pamọ́ àwọn ibi ó fi ara sin,

bẹ́̀ ìwọ yóò fi mọ̀ , Èmi ni Olúwa,

Ọlọ́run Israẹli, ẹni ó ́ pẹ̀orúkọ rẹ.

4 Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi

àti Israẹli ẹni mo yàn,

Mo ́ pẹ̀orúkọ rẹ,

mo gbé oyè kan ́ lórí

ó tilẹ̀ jẹ́ ìwọ gbà .

5 Èmi ni Olúwa, àti ẹlòmíràn;

yàtọ̀ èmi ọlọ́run kan,

Èmi yóò fún okun,

o tilẹ̀ ì gbà ,

6 o fi jẹ́ láti ìlà-oòrùn

títí ibi ìwọ̀ rẹ̀

ènìyàn le mọ̀, ẹnìkan lẹ́yìn mi.

Èmi ni Olúwa, lẹ́yìn mi ẹlòmíràn mọ́.

7 Mo ìmọ́lẹ̀, mo òkùnkùn,

Mo àlàáfíà , Mo àjálù;

Èmi Olúwa ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí.

8 "Ìwọ ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀;

jẹ́ àwọsánmọ̀ ó rọ̀ ́ sílẹ̀.

Jẹ́ ilẹ̀ ó yanu gbagada,

jẹ́ ìgbàlà ó dìde sókè,

jẹ́ òdodo ó dàgbà pẹ̀rẹ̀;

Èmi Olúwa ni ó ti a.

9 "Ègbé ni fún ènìyàn ó ń Ẹlẹ́dàá rẹ̀ ,

ẹni òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì ó lórí ilẹ̀.

Ǹjẹ́ amọ̀ sọ fún amọ̀kòkò, :

ni ohun ò ń ṣe?

Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ sọ ,

Òun ọwọ́?’

10 Ègbé ni fún ẹni ó sọ fún baba rẹ̀ ,

ni o ?

tàbí ìyá rẹ̀,

ni ìwọ ti ?

11 "Ohun Olúwa nìyìí,

Ẹni Mímọ́ Israẹli, àti Ẹlẹ́dàá rẹ̀.

Nípa ohun ó ń bọ̀,

ǹjẹ́ o ń bi léèrè nípa àwọn ọmọ mi,

tàbí o pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi ?

12 Èmi ni ẹni ó ilẹ̀ ayé

ó da ọmọ ènìyàn sórí i rẹ̀.

Ọwọ́ mi ni ó ti ta àwọn ̀run;

mo àwọn àgbájọ ìràwọ̀ rẹ̀ síta.

13 Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi.

Èmi yóò gbogbo ̀rẹ̀ ó tọ́.

Òun yóò tún ìlú mi kọ́

yóò àwọn àtìpó mi sílẹ̀,

ṣùgbọ́n í ṣe fún owó tàbí ̀bùn kan,

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun ."

14 Ohun Olúwa nìyìí:

"Àwọn èròjà ilẹ̀ Ejibiti àti àwọn ọjà ilẹ̀ Kuṣi,

àti àwọn Sabeani

wọn yóò sọ́dọ̀ rẹ

wọn yóò jẹ́ tìrẹ;

wọn yóò máa wọ́ tẹ̀lẹ́yìn,

wọn yóò máa lọ́wọ̀̀wọ́.

Wọn yóò máa foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀,

wọn yóò máa bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ ,

Nítòótọ́ Ọlọ́run pẹ̀rẹ ṣí ẹlòmíràn;

ọlọ́run mìíràn.’ "

15 Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run ó fi ara rẹ̀ pamọ́,

Ìwọ Ọlọ́run àti Olùgbàlà Israẹli,

16 Gbogbo àwọn ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò

wọn yóò kan àbùkù;

gbogbo wọn ni yóò bọ́ sínú àbùkù papọ̀.

17 Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa

pẹ̀ìgbàlà ayérayé;

a yóò kàn yín lábùkù tàbí a dójútì yín,

títí ayé àìnípẹ̀kun.

18 Nítorí èyí ni ohun Olúwa ,

ẹni ó àwọn ̀run,

Òun ni Ọlọ́run;

ẹni ó mọ ó ayé,

Òun ṣe é;

Òun a láti lófo,

ṣùgbọ́n ó ṣe é a máa gbé ibẹ̀,

Òun :

"Èmi ni Olúwa,

ṣí ẹlòmíràn.

19 Èmi sọ̀rọ̀ níbi ó fi ara sin,

láti ibìkan ilẹ̀ òkùnkùn,

Èmi ì sọ fún àwọn ìran Jakọbu ,

mi lórí asán.

Èmi Olúwa sọ òtítọ́,

Mo sọ èyí ó tọ̀.

20 "ara yín jọ ;

kórajọ, ̀yin ìsáǹsá láti àwọn orílẹ̀-èdè .

Aláìmọ̀kan ni àwọn ó ń ru ère igi káàkiri,

wọ́n gbàdúrà àwọn òrìṣà le gba ni.

21 Jẹ́ a mọ ohun yóò ṣẹlẹ̀, fihàn ,

jẹ́ wọn jọ dámọ̀ràn papọ̀.

Ta ti sọ èyí lọ́jọ́ o ti pẹ́,

ta ti èyí láti àtètèkọ́ṣe?

í ha á ṣe Èmi, Olúwa?

Àti Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi,

Ọlọ́run olódodo àti olùgbàlà;

ẹlòmíràn àfi èmi.

22 "Yípadà mi a gbà ́ ,

̀yin ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé;

nítorí Èmi ni Ọlọ́run ṣí ẹlòmíràn.

23 Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra,

ẹnu mi ni ó ti sọ ́ pẹ̀gbogbo ipá mi,

̀rọ̀ náà a yóò parẹ́.

Níwájú mi ni gbogbo orúnkún yóò wólẹ̀;

nípa mi ni gbogbo ahọ́n yóò búra.

24 Wọn yóò sọ ti èmi, Nínú Olúwa nìkan ni

òdodo àti agbára .’ "

Gbogbo àwọn ó ti bínú ;

yóò sọ́dọ̀ rẹ̀ a ó dójútì wọn.

25 Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli

ni a ó òdodo, a o gbé wọn ga.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-