Publicidade

Isaías 59

̀ṣẹ̀, ìjẹ́wọ́ àti ìràpadà

1 Lódodo ọwọ́ Olúwa kúrú láti gbàlà,

tàbí etí rẹ̀ wúwo láti gbọ́.

2 Ṣùgbọ́n ̀ṣẹ̀ yín ti yín kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run yín;

̀ṣẹ̀ yín ti fi ojú u rẹ̀ pamọ́ fún un yín

bẹ́̀ òun fi le gbọ́.

3 Nítorí ọwọ́ yín di aláìmọ́ fún ̀jẹ̀,

àti ìka ọwọ́ yín fún ̀bi.

Ètè yín ń pa irọ́ púpọ̀,

ahọ́n yín ń sọ̀rọ̀ nǹkan ibi.

4 ẹni ó béèrè fún ìdájọ́ òdodo;

ẹni ó ro ẹjọ́ rẹ̀ pẹ̀òtítọ́.

Wọ́n gbẹ́kẹ̀àwíjàre asán àti ̀rọ̀ irọ́;

wọ́n lóyún ìkà, wọn wàhálà.

5 Wọn ń pa ̀yin paramọ́lẹ̀

wọn ń ta owú aláǹtakùn.

Ẹnikẹ́ni ó jẹ ẹyin wọn yóò ,

àti nígbà a pa ̀kan, paramọ́lẹ̀ ni ó jáde.

6 Òwú wọn wúlò fún aṣọ rírán;

wọn fi aṣọ wọ́n hun bo ara wọn.

Iṣẹ́ wọn jẹ́ ti ibi, ìwà jàǹdùkú kún ọwọ́ wọn.

7 59.7-8: Ro 3.15-17. Ẹsẹ̀ wọn yára bọ́ sínú ̀ṣẹ̀;

wọ́n yára láti ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀.

Èrò wọn jẹ́ èrò ibi;

ìparun àti ìdahoro ni ó ṣíṣe àmì ̀wọn.

8 ̀àlàáfíà èyí ni wọn mọ̀;

òdodo ojú ̀wọn

wọ́n ti sọ wọ́n ̀kọ́rọkọ̀rọ,

ẹni ó tọ ̀yìí yóò àlàáfíà.

9 Nítorí èyí ni ̀tọ́ fi jìnnà wa,

àti òdodo fi tẹ̀ lọ́wọ́.

A ń ìmọ́lẹ̀, ṣùgbọ́n gbogbo rẹ̀ jẹ́ òkùnkùn;

ìmọ́lẹ̀, ṣùgbọ́n à ń rìn nínú òjìji.

10 Gẹ́gẹ́ afọ́à ń táràrà lọ lẹ́gbẹ̀́ ògiri

a ń ̀wa gẹ́gẹ́ ènìyàn ojú.

̀sán gangan ni à ń kọsẹ̀ ẹni alẹ́ ni;

láàrín alágbára àwa dàbí òkú.

11 Gbogbo wa ń i beari;

àwa pohùnréré ẹkún àdàbà.

A ń ìdájọ́ òdodo ṣùgbọ́n ; à ń wọ́fún ìtúsílẹ̀,

ṣùgbọ́n ó jìnnà réré.

12 Nítorí àwọn àṣìṣe wa pọ̀ níwájú rẹ,

àwọn ̀ṣẹ̀ wa ń jẹ́rìí takò .

Àwọn àìṣedéédéé wa pẹ̀wa,

àwa pẹ̀mọ àìṣedéédéé wa,

13 ̀tẹ̀ àti àrékérekè wa Olúwa,

kíkọ ̀yìn wa Ọlọ́run,

dídá yánpọnyánrin àti ìnilára sílẹ̀,

pípààrọ̀ ọkàn wa ti gbèrò síta.

14 Nítorí èyí ni a ṣe ìdájọ́ òdodo sẹ́yìn,

àti ti òdodo dúró lókèèrè;

òtítọ́ ti ṣubú òpópó ̀,

òdodo le è wọlé.

15 A òtítọ́ mọ́,

àti ẹni ó fun ibi di ìjẹ.

Olúwa ó ọkàn rẹ̀ bàjẹ́

ìdájọ́ òdodo.

16 Òun i ẹnìkan,

àyà ó ẹnìkan láti ṣèrànwọ́;

nítorí apá òun tìkára rẹ̀ ṣiṣẹ́ ìgbàlà fún ara rẹ̀,

àti òdodo òun tìkára rẹ̀ gbé e .

17 59.17: Ef 6.14,17; 1Tẹ 5.8. Ó gbé òdodo wọ̀ gẹ́gẹ́ ìgbàyà rẹ̀,

àti àṣíborí ìgbàlà orí rẹ̀;

ó gbé ̀̀san wọ̀

ó ara rẹ̀ ìtara ̀.

18 Gẹ́gẹ́ ohun wọ́n ti ṣe,

bẹ́̀ ni yóò san án

ìbínú fún àwọn ̀rẹ̀

àti ̀san fún àwọn ̀rẹ̀;

òun yóò san án fún àwọn erékùṣù ̀tọ́ wọn.

19 59.19: Mt 8.11; Lk 13.29. Láti ìwọ̀-oòrùn, àwọn ènìyàn yóò bẹ̀orúkọ Olúwa,

àti láti ìlà-oòrùn, wọn yóò bọ̀wọ̀ fún ògo rẹ̀.

Nítorí òun yóò gẹ́gẹ́ i rírú omi

èyí èémí Olúwa ń lọ.

20 59.20-21: Ro 11.26-27. "Olùdáǹdè yóò Sioni,

àwọn ó Jakọbu ó

ronúpìwàdà ̀ṣẹ̀ wọn," ni Olúwa .

21 "Àti fún èmi, májẹ̀mi pẹ̀wọn nìyìí," ni Olúwa , "̀mi, ó nínú yín, àti ̀rọ̀ mi mo ti fi ẹnu yín, yóò kúrò lẹ́nu yín, tàbí lẹ́nu àwọn ọmọ yín, tàbí láti ẹnu àwọn ìrandíran wọn láti àkókò yìí lọ àti títí láéláé," ni Olúwa .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-