Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaías 63

Ọjọ́ ̀san àti ìràpadà Ọlọ́run

1 63.1-6: Isa 34; Jr 49.7-22; El 25.12-14; 35; Am 1.11-12; Ml 1.2-5. Ta eléyìí ó Edomu ,

ti òun ti aṣọ àrẹpọ́n láti Bosra ?

Ta eléyìí, ó ògo nínú aṣọ rẹ̀,

ó ń yan bọ̀ nínú ọláńlá agbára rẹ̀?

"Èmi ni ẹni ó ń sọ̀rọ̀ nínú òdodo

ó ipa láti gbàlà."

2 Èéṣe aṣọ yín fi pupa

gẹ́gẹ́ i tàwọn ń ṣiṣẹ́ ìfúntí?

3 63.3: If 19.15. "Èmi nìkan ti tẹ ìfúntí wáìnì;

láti àwọn orílẹ̀-èdè ẹnikẹ́ni pẹ̀mi.

Mo tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ ìbínú mi

mo tẹ̀ wọ́n rẹ́ ìrunú mi

̀jẹ̀ wọn fọ́n aṣọ mi,

mo da àbàwọ́n gbogbo aṣọ mi.

4 Nítorí ọjọ́ ̀san ọkàn mi

àti ọdún ìràpadà mi ti .

5 Mo , ṣùgbọ́n ẹnìkan láti ṣe ìrànwọ́.

Àyà ẹnikẹ́ni ṣèrànwọ́;

nítorí náà apá mi ni ó ṣiṣẹ́ ìgbàlà fún mi

àti ìrunú mi ni ó gbé mi .

6 Mo tẹ orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀ nínú ìbínú mi;

nínú ìrunú mi mo jẹ́ wọ́n mu

mo da ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀ lórí erùpẹ̀."

Ìyìn àti àdúrà

7 Èmi yóò sọ nípa àánú Olúwa,

ìṣe rẹ gbogbo ó yẹ a yìn ín fún,

gẹ́gẹ́ ohun Olúwa ti ṣe fún wa,

bẹ́̀ ni, ohun rere gbogbo

ó ti ṣe fún ilé Israẹli,

gẹ́gẹ́ àánú àti ̀pọ̀lọpọ̀ oore rẹ̀.

8 Ó , "Lóòtítọ́ ènìyàn mi ni wọ́n,

àwọn ọmọ yóò jẹ́ òpùrọ́ fún mi";

bẹ́̀ ni, ó di Olùgbàlà wọn.

9 Nínú gbogbo ìpọ́njú wọn, inú òun pẹ̀bàjẹ́

àti angẹli ó níwájú rẹ̀ gbà wọ́n .

Nínú ìfẹ́ àti àánú rẹ̀, ó wọ́n padà;

ó gbé wọn sókè ó pọ̀n wọ́n

gbogbo ọjọ́ ìgbà n .

10 Síbẹ̀síbẹ̀ wọ́n ṣọ̀tẹ̀

wọ́n ba ̀Mímọ́ rẹ̀ nínú jẹ́.

Bẹ́̀ ni ó yípadà ó di ̀wọn

òun tìkára rẹ̀ wọn .

11 63.11: Hb 13.20. Lẹ́yìn náà ni àwọn ènìyàn rẹ̀ rántí ọjọ́ ìgbà n ,

àwọn ọjọ́ Mose àti àwọn ènìyàn rẹ̀

níbo ni ẹni náà ó wọn la Òkun ,

pẹ̀olùṣọ́-àgùntàn agbo ẹran rẹ̀?

Níbo ni ẹni náà ó rán

̀Mímọ́ rẹ̀ sáàrín wọn,

12 ta ni ó rán apá ògo ti agbára rẹ̀

láti apá ̀tún Mose,

ta ni ó pín omi níwájú wọn,

láti gba òkìkí ayérayé fún ara rẹ̀,

13 ta ni ó síwájú wọn la àwọn ̀gbun ?

Gẹ́gẹ́ ẹṣin ni gbangba ìlú wọn kọsẹ̀;

14 gẹ́gẹ́ ̀wọ́ ẹran ó lọ pápá oko,

a fún wọn ìsinmi láti ọwọ́ ̀Olúwa.

Báyìí ni ṣe tọ́ àwọn ènìyàn yín

láti fún ara yín orúkọ kan ó lógo.

15 Bojú wolẹ̀ láti ̀run o i

láti ìtẹ́ ògo rẹ, mímọ́ àti ológo.

Níbo ni ìtara àti agbára rẹ ?

Ìwà jẹ́́jẹ́ rẹ àti àánú rẹ ni a

ti kúrò níwájú wa.

16 Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa,

ó tilẹ̀ jẹ́ Abrahamu mọ̀

tàbí Israẹli mọ ẹni à á ṣe;

ìwọ, Olúwa ni Baba wa,

Olùràpadà wa láti ìgbà n ni orúkọ rẹ.

17 Èéṣe Olúwa o fi jẹ́ a ṣáko kúrò ojú ̀rẹ

o ṣé àyà wa le bẹ́̀ àwa fi bọ̀wọ̀ fún ?

Padà nítorí àwọn ìránṣẹ́ rẹ,

àwọn ̀ṣe ogún ìní rẹ.

18 Fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ fi gba ibi mímọ́ rẹ,

ṣùgbọ́n nísinsin yìí àwọn ̀wa ti tẹ ibi mímọ́ rẹ mọ́lẹ̀.

19 Àwa jẹ́ tìrẹ láti ìgbà n ;

ṣùgbọ́n ìwọ ì jẹ ọba wọn lórí,

a ì wọ́n mọ́ orúkọ rẹ.

Veja também