Publicidade

Isaías 46

Àwọn Ọlọ́run Babeli

1 Beli tẹrí i rẹ̀ ba, Nebo bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀;

àwọn ère wọn ni àwọn ẹranko .

Àwọn ère wọ́n ń káàkiri ti di

àjàgà wọn lọ́rùn,

ẹrù fún àwọn àárẹ̀ .

2 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ wọ́n foríbalẹ̀ papọ̀;

wọn gba ẹrù náà,

àwọn pẹ̀ni a lọ ìgbèkùn.

3 "Tẹ́mi, ìwọ ilé Jakọbu,

gbogbo ̀yin ó ṣẹ́nínú ilé Israẹli,

ìwọ mo ti gbéró láti ìgbà o ti nínú oyún,

mo ti ń pọ̀n láti ìgbà a ti .

4 Pẹ̀lúpẹ̀àwọn arúgbó àti ewú orí yín,

Èmi ni ẹni náà, Èmi ni ẹni yóò gbé .

Èmi ti mọ ́, èmi yóò gbé ;

Èmi yóò ́ èmi ó gbà ́ sílẹ̀.

5 "Ta ni ìwọ yóò fi tàbí ta ni èmi yóò dọ́gba?

Ta ni ìwọ yóò fi ṣe àkàwé mi

àwa yóò jọ fi ara ara?

6 ̀pọ̀ da wúrà sílẹ̀ nínú àpò wọn

wọ́n wọn fàdákà lórí òsùwọ̀n;

wọ́n bẹ alágbẹ̀dẹ lọ́wẹ̀ láti fi wọ́n ṣe òrìṣà,

wọn tẹríba láti sìn ín.

7 Wọ́n gbé e èjìká wọn, wọ́n wọ́n,

wọ́n gbé e ààyè rẹ̀ níbẹ̀ ni ó dúró .

Láti ibẹ̀ náà le è paradà.

ènìyàn tilẹ̀ pariwo e lórí, òun le è dáhùn;

òun gbà á nínú ìyọnu rẹ̀.

8 "Rántí èyí, fi í ọkàn rẹ,

fi ọkàn rẹ, ̀yin ọlọ̀tẹ̀.

9 Rántí àwọn nǹkan àtẹ̀yìnwá, àwọn ti àtijọ́-tijọ́;

Èmi ni Ọlọ́run, ẹlòmíràn;

Èmi ni Ọlọ́run, ẹlòmíràn ì mi.

10 Mo fi òpin hàn láti ìbẹ̀rẹ̀ ,

láti àtètèkọ́ṣe, ohun ó ń bọ̀ .

Mo , Ète mi yóò dúró,

àti èmi yóò ṣe ohun ó .

11 Láti ìlà-oòrùn ni mo ti pe ẹyẹ ajẹran ;

láti ̀jíjìn réré, ọkùnrin kan yóò ète mi ṣẹ.

Ohun mo ti sọ, òun ni èmi yóò ṣẹ;

èyí mo ti gbèrò, òun ni èmi yóò ṣe.

12 Gbọ́ tèmi, ̀yin alágídí ọkàn,

ìwọ ó jìnnà òdodo.

13 Èmi ń òdodo mi bọ̀ nítòsí,

tilẹ̀ jìnnà rárá;

àti ìgbàlà mi ni a yóò dádúró.

Èmi yóò fún Sioni ìgbàlà

ògo mi fún Israẹli.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-