Publicidade

Isaías 50

̀ṣẹ̀ Israẹli àti ìgbọ́ràn ìránṣẹ́

1 Ohun Olúwa nìyìí:

"Níbo ni ìwé-ẹ̀ìkọ̀sílẹ̀ ìyá rẹ

èyí mo fi e lọ?

Tàbí èwo nínú àwọn olùyánilówó mi

ni mo ́ fún?

Nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ ni a fi ́;

nítorí àìṣedéédéé rẹ ni a fi ìyá rẹ lọ.

2 Nígbà mo , èéṣe a fi ẹnìkan?

Nígbà mo , èéṣe fi ẹnìkan láti dáhùn?

Ọwọ́ mi a kúrú láti gbà ́?

Èmi ha agbára láti gbà ́ ?

Nípa ìbáwí lásán, Èmi gbẹ omi òkun,

Èmi àwọn odò aṣálẹ̀;

àwọn ẹja wọn fún àìsí omi

wọ́n fún òǹgbẹ.

3 Èmi fi òkùnkùn bo sánmọ̀

mo fi aṣọ ̀fọ̀ ṣe ìbòrí rẹ̀."

4 Olúwa Olódùmarè ti fún mi ni ahọ́n a fi iṣẹ́ rán,

láti mọ àwọn ̀rọ̀ ó gbé àwọn aláàárẹ̀ .

O mi láràárọ̀,

o etí mi láti gbọ́ gẹ́gẹ́ ẹni à ń kọ́.

5 Olúwa Olódùmarè ti ṣí mi etí,

bẹ́̀ ni èmi ṣọ̀tẹ̀ ;

Èmi padà sẹ́yìn.

6 Mo ṣí ̀yìn mi sílẹ̀ fún àwọn ó ń ,

àti ̀rẹ̀kẹ́ mi fún àwọn ń fa irùngbọ̀n mi;

Èmi fi ojú mi pamọ́

kúrò lọ́wọ́ ẹlẹ́àti ìyọṣùtì .

7 Nítorí Olúwa Olódùmarè ràn lọ́wọ́,

a yóò dójútì .

Nítorí náà ni mo ṣe gbé ojú mi òkúta akọ

èmi mọ , ojú .

8 Ẹni ó mi láre nítòsí.

Ta ni ẹni náà yóò fẹ̀sùn kàn ?

Jẹ́ a kojú ara wa!

Ta ni olùfisùn mi?

Jẹ́ ó lójú!

9 Olúwa Olódùmarè ni ó ń ràn lọ́wọ́.

Ta ni ẹni náà yóò mi lẹ́bi?

Gbogbo wọn yóò gbó aṣọ;

kòkòrò ni yóò jẹ wọn run.

10 Ta ni nínú yín ó bẹ̀Olúwa

ó ń gbọ́rọ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ lẹ́nu?

Jẹ́ ẹni ń rìn òkùnkùn

ìmọ́lẹ̀,

ó gbẹ́kẹ̀orúkọ Olúwa

o gbẹ́kẹ̀Ọlọ́run rẹ̀.

11 Ṣùgbọ́n àkókò yìí, gbogbo ̀yin ti ń tanná

ń fi pèsè iná ìléwọ́ fún ara yín,

lọ, máa rìn nínú ìmọ́lẹ̀ iná yín,

àti nínú ẹta iná ti .

Èyí ni yóò jẹ́ tiyín láti ọwọ́ mi .

̀yin ó dùbúlẹ̀ nínú ìrora.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-