Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaías 54

Ògo ọjọ́ iwájú ti Sioni

1 54.1: Ga 4.27. "Kọrin, ìwọ obìnrin àgàn,

ìwọ ì bímọ ;

orin, fún ayọ̀,

̀yin ì rọbí ;

nítorí púpọ̀ ni ọmọ àwọn obìnrin ìsọdahoro

ju ti ẹni ó ọkọ,"

ni Olúwa .

2 Fẹ ibi àgọ́ rẹ lójú i,

fẹ aṣọ àgọ́ rẹ ó gbòòrò i,

ṣe a dúró;

sọ okùn rẹ di gígùn,

òpó rẹ lágbára i.

3 Nítorí ìwọ ó fẹ̀ sọ́tùn àti òsì;

ìrandíran rẹ yóò jogún àwọn orílẹ̀-èdè,

wọn yóò ahoro àwọn ìlú wọn.

4 "ṣe bẹ̀, ìtìjú ṣubú ́.

ṣe bẹ̀ìdójútì, a yóò kàn ́ lábùkù.

Ìwọ yóò gbàgbé ìtìjú ìgbà èwe e rẹ,

ìwọ yóò rántí ̀gàn ìgba-opo rẹ mọ́.

5 Nítorí Ẹlẹ́dàá rẹ ni ọkọ rẹ

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀

Ẹni Mímọ́ Israẹli ni Olùràpadà rẹ;

a ń é Ọlọ́run gbogbo ayé.

6 Olúwa yóò ́ padà

àfi ẹni obìnrin a kọ̀sílẹ̀

a lọ́kàn jẹ́

obìnrin a fẹ́ ̀dọ́,

a jákulẹ̀," ni Olúwa .

7 "Fún ìgbà díẹ̀ ni mo kọ̀ ́ sílẹ̀,

ṣùgbọ́n pẹ̀ọkàn ìyọ́èmi yóò

padà .

8 ríru ìbínú.

Mo fi ojú pamọ́ fún fún ìṣẹ́kan,

ṣùgbọ́n pẹ̀àánú àìnípẹ̀kun

Èmi yóò síjú àánú ́,"

ni Olúwa Olùdáǹdè rẹ .

9 "mi, èyí dàbí i àwọn ọjọ́ Noa,

nígbà mo búra àwọn omi

Noa yóò tún bo ilẹ̀ ayé mọ́.

Bẹ́̀ ni nísinsin yìí mo ti búra láti ṣe bínú ,

bẹ́̀ ni èmi yóò mọ́.

10 a tilẹ̀ mi àwọn òkè ńlá

a ṣí àwọn òkè kékeré nídìí,

síbẹ̀síbẹ̀ ìfẹ́ àìkùnà mi fún yóò yẹ̀ láéláé

tàbí májẹ̀àlàáfíà ni a ó kúrò,"

ni Olúwa, ẹni ó síjú àánú ́ .

11 54.11-12: If 21.19. Ìwọ ìlú a pọ́n lójú, ìjì ń gbá kiri

a nínú,

Èmi yóò fi òkúta Tikuosi kọ́

àti ìpìlẹ̀ rẹ pẹ̀safire.

12 Èmi yóò fi iyùn ṣe odi rẹ,

àwọn ẹnu-ọ̀ni a ó fi ohun èlò dáradára fún,

àti àwọn ògiri rẹ pẹ̀òkúta iyebíye.

13 54.13: Jh 6.45. Gbogbo ̀dọ́mọkùnrin rẹ ni Olúwa yóò kọ́,

àlàáfíà àwọn ọmọ rẹ yóò jẹ́ ńlá àti púpọ̀.

14 òdodo ni a ó fi ìdí rẹ kalẹ̀

ìwà ipá yóò jìnnà

o bẹ̀ohunkóhun,

ìpayà la ó kúrò pátápátá;

súnmọ́ ̀dọ̀ rẹ.

15 ẹnikẹ́ni tilẹ̀ , jẹ́ láti ọwọ́ mi;

ẹnikẹ́ni ó ni yóò túúbá fún .

16 "Kíyèsi i, èmi ni ó alágbẹ̀dẹ

ń fẹ́ iná èédú iná

ó ń ohun èlò ó iṣẹ́ rẹ mu.

Èmi náà ni ẹni ó apanirun láti ṣe iṣẹ́ ibi;

17 ohun ìjà a ṣe yóò ṣe nǹkan,

àti gbogbo ahọ́n ó dìde ìdájọ́ ni ìwọ ó ̀bi.

Èyí ni ogún àwọn ìránṣẹ́ Olúwa,

èyí ni ìdáláre wọn láti ̀dọ̀ mi,"

ni Olúwa .

Veja também