Publicidade

Isaías 57

1 Olódodo ṣègbé

ẹnìkan ó ó lọ́kàn ara rẹ̀;

a àwọn ẹni mímọ́ lọ,

ṣí ẹni

a ti àwọn olódodo lọ

láti yọ wọ́n kúrò nínú ibi.

2 Gbogbo àwọn ń rìn déédé

ń wọ inú àlàáfíà;

wọ́n ìsinmi wọ́n ti ń sùn nínú ikú.

3 "Ṣùgbọ́n súnmọ́ ìhìn-ín, ̀yin ọmọ aláfọ̀ṣẹ,

̀yin irú-ọmọ panṣágà àti àgbèrè!

4 Ta ni ó fi ń ṣẹlẹ́?

Ta ni o ń yọ ṣùtì

o yọ ahọ́n síta?

̀yin í ha ṣe ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn ,

àti ìran àwọn òpùrọ́?

5 gbinájẹ fún ìṣekúṣe láàrín igi óákù

àti lábẹ́ gbogbo igi ń gbilẹ̀;

fi àwọn ọmọ yín ẹbọ nínú kòtò jíjìn

àti lábẹ́ àwọn pàlàpálá òkúta.

6 Àwọn ère ó àárín òkúta dídán

wọ́n n , nínú kòtò jíjìn ni ìpín in yín;

àwọ̀n ni ìpín in yín.

Bẹ́̀ ni, wọn ni ti ta ọrẹ ohun mímu yín sílẹ̀

àti láti ta ọrẹ ìyẹ̀fun.

Nítorí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ǹjẹ́ ó yẹ

n dáwọ́ dúró?

7 Ìwọ ti ṣe ibùsùn rẹ lórí òkè gíga ó rẹwà;

níbẹ̀ ni lọ láti lọ ṣe ìrúbọ yín.

8 Lẹ́yìn àwọn ìlẹ̀kùn yín àti òpó ìlẹ̀kùn yín

níbẹ̀ ni fi àwọn àmì òrìṣà yín .

kíkọ̀ sílẹ̀, ṣí ibùsùn yín sílẹ̀,

gun orí rẹ̀ lọ, ṣí i sílẹ̀ gbagada;

ṣe àdéhùn pẹ̀àwọn fẹ́ràn ibùsùn wọn,

̀yin ń wo ìhòhò wọn.

9 ̀yin lọ Moleki pẹ̀òróró olifi

fi kún òórùn dídùn yín.

rán ikọ̀ yín lọ jìnnà réré;

sọ̀kalẹ̀ ibojì pẹ̀!

10 Àwọn ̀yín gbogbo ti àárẹ̀ ba á yín,

ṣùgbọ́n sọ , ìrètí mọ́?’

okun kún agbára yín,

nípa bẹ́̀ òòyì kọ́ yín.

11 "Ta ni ó ń yín láyà ń yín lẹ́

fi ń ṣèké mi,

àti ̀yin fi rántí mi

tàbí nínú ọkàn yín?

Ǹjẹ́ í ṣe nítorí dídákẹ́ jẹ́́ mi fún ìgbà pípẹ́

̀yin fi bẹ̀mi?

12 Èmi yóò ṣí òdodo yín páyà àti iṣẹ́ yín,

wọn yóò ṣe yín àǹfààní.

13 Nígbà kígbe fún ìrànlọ́wọ́

jẹ́ àkójọ àwọn ère yín gbà yín!

Atẹ́gùn yóò gbá gbogbo wọn lọ,

èémí lásán làsàn ni yóò gbá wọn lọ.

Ṣùgbọ́n ẹni ó fi ṣe ààbò rẹ̀

ni yóò jogún ilẹ̀ náà

yóò jogún òkè mímọ́ mi."

Ìtùnú fún àwọn oníròbìnújẹ́

14 A ó sọ :

"Tún mọ, tún mọ, tún ̀náà ṣe!

àwọn ohun ìkọ̀sẹ̀ kúrò ̀àwọn ènìyàn mi."

15 Nítorí èyí ni ohun Ẹni gíga àti ọlọ́jùlọ

ẹni ó títí láé, orúkọ rẹ̀ jẹ́ mímọ́:

"Mo ń gbé ibi gíga àti ibi mímọ́,

ṣùgbọ́n pẹ̀ẹni n ó ìròbìnújẹ́ àti ̀ìrẹ̀lẹ̀,

láti sọ ̀onírẹ̀lẹ̀ náà

àti láti sọ ̀oníròbìnújẹ́ n .

16 Èmi yóò fẹ̀sùn kan ni títí láé,

tàbí n máa bínú á,

nítorí nígbà náà ni ọkàn ènìyàn yóò

rẹ̀wẹ̀níwájú mi

èémí ènìyàn mo ti .

17 Inú mi nítorí ̀ṣẹ̀ ̀kánjúwà rẹ̀;

mo fìyà jẹ ́, mo fojú mi pamọ́ ìbínú;

síbẹ̀, ó tẹ̀síwájú nínú tinú-mi-ni n ó ṣe ̀rẹ̀.

18 Èmi ti ̀rẹ̀ gbogbo, ṣùgbọ́n Èmi yóò ó sàn;

Èmi yóò tọ́ ṣọ́n ó ìtùnú tọ̀ ́ ,

19 dídá ìyìn ètè àwọn ń ṣọ̀fọ̀ Israẹli.

Àlàáfíà, àlàáfíà fún àwọn ó lókèèrè àti nítòsí,"

ni Olúwa , "Àti , Èmi yóò wo wọ́n sàn."

20 Ṣùgbọ́n àwọn ìkà dàbí i ríru Òkun

le è sinmi,

ìgbì rẹ̀ ń pẹ̀tẹ̀pẹ́tẹ̀ àti ẹrọ̀fọ̀ sókè.

21 "àlàáfíà fún àwọn ìkà," ni Ọlọ́run mi .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-