Publicidade

Isaías 58

Àwẹ̀ tòótọ́

1 "Kígbe rẹ̀ sókè, ṣe fàsẹ́yìn.

Gbé ohùn rẹ sókè i ti fèrè.

Jẹ́ ó di mọ̀ fún àwọn ènìyàn mi, ̀tẹ̀ wọn,

àti fún ilé Jakọbu ̀ṣẹ̀ wọn.

2 Nítorí ọjọ́ ọjọ́ ni wọ́n ń mi kiri;

wọ́n ṣe ẹni ìtara láti mọ ̀mi,

àfi ẹni wọ́n jẹ́ orílẹ̀-èdè kan ń ṣe ohun ó tọ̀

òun ì kọ àṣẹ Ọlọ́run rẹ̀.

Wọ́n ń béèrè lọ́wọ́ mi fún ìpinnu nìkan

wọ́n ṣe ẹni ń tara fún Ọlọ́run láti súnmọ́ ̀dọ̀ wọn.

3 Wọ́n , Èéṣe àwa fi ń gbààwẹ̀,

ìwọ ì ?

Èéṣe àwa fi rẹra wa sílẹ̀,

ìwọ ì ṣe àkíyèsí?

"Síbẹ̀síbẹ̀ ọjọ́ àwẹ̀ yín, ̀yin ń ṣe ó ti yín

ń pọ́n àwọn òṣìṣẹ́ yín gbogbo lójú.

4 Àwẹ̀ yín parí nínú ìjà àti asọ̀,

àti lílu ọmọnìkejì ẹni pa pẹ̀ìkùùkuu.

̀yin le è gbààwẹ̀ ti ń ṣe lónìí

retí a gbọ́ ohùn un yín ibi gíga.

5 Ǹjẹ́ èyí ha ni irú àwẹ̀ mo yàn ,

ọjọ́ kan ṣoṣo fún ènìyàn láti rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀?

Ó ha jẹ pe ènìyàn tẹ orí rẹ̀ ba i koríko lásán ni

àti sísùn nínú aṣọ ̀fọ̀ àti eérú?

Ṣé ohun ̀ ń àwẹ̀ nìyí,

ọjọ́ ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa?

6 "Ǹjẹ́ irú àwẹ̀ mo ti yàn kọ́ ni èyí:

láti gbogbo ̀wọ̀n àìṣòdodo

àti láti gbogbo okùn àjàgà,

láti gbogbo àwọn ti à ń ni lára sílẹ̀

àti láti fọ́ gbogbo àjàgà?

7 í ha á ṣe láti pín oúnjẹ yín fún àwọn ebi ń pa

àti láti pèsè ibùgbé fún àwọn òtòṣì ń rìn káàkiri.

Nígbà ẹni ó níhòhò, láti daṣọ ó,

àti láti ṣe àwọn ìbátan yín sẹ́yìn?

8 Nígbà náà ni ìmọ́lẹ̀ rẹ yóò tàn jáde òwúrọ̀

àti ìmúláradá rẹ yóò farahàn kíákíá;

nígbà náà ni òdodo rẹ yóò lọ níwájú rẹ,

ògo Olúwa yóò jẹ́ ààbò lẹ́yìn rẹ.

9 Nígbà yìí ni ̀yin yóò , Olúwa yóò dáhùn;

̀yin yóò kígbe fún ìrànlọ́wọ́, òun yóò , Èmi nìyí.

"ìwọ àjàgà aninilára,

nínà ìka àlébù àti sísọ ̀rọ̀ asán kúrò láàrín rẹ,

10 àti ̀yin ara yín owó nítorí àwọn ebi ń pa

tẹ́ ìfẹ́ àwọn à ń ni lára lọ́rùn,

nígbà náà ni ìmọ́lẹ̀ yín yóò ràn nínú òkùnkùn,

àti òru yín yóò dàbí ̀sán gangan.

11 Olúwa yóò máa tọ́ yín nígbà gbogbo;

òun yóò tẹ́ gbogbo àìní yín lọ́rùn ilẹ̀ oòrùn ń tan ìmọ́lẹ̀

yóò fún egungun rẹ lókun.

Ìwọ yóò dàbí ọgbà a bomirin dáradára,

àti orísun omi rẹ̀ í gbẹ.

12 Àwọn ènìyàn rẹ yóò tún ahoro àtijọ́ kọ́

wọn yóò gbé ìpìlẹ̀ àtijọ́-tijọ́

a ó ́ alátúnṣe ògiri ó ti

àti olùmúbọ̀sípò àwọn òpópónà ènìyàn gbé inú rẹ̀.

13 "ìwọ pa ẹsẹ̀ rẹ mọ́ kúrò nínú bíba ọjọ́ ìsinmi jẹ́,

àti ṣíṣe ó ti ́ ni ọjọ́ mímọ́ mi,

ìwọ pe ọjọ́ ìsinmi ohun dídùn

àti ọjọ́ mímọ́ Olúwa ohun ̀wọ̀

àti ìwọ bu ọlá fún un láti máa ̀tìrẹ lọ

àti láti ṣe ó ti ́ tàbí

o máa sọ̀rọ̀ aláìníláárí,

14 nígbà náà ni ìwọ yóò ayọ̀ nínú Olúwa rẹ,

èmi yóò jẹ́ ìwọ ó máa gun ibi gíga ilẹ̀ ayé,

àti láti máa jàdídùn ìní ti

Jakọbu baba rẹ."

Ẹnu Olúwa ni ó ti sọ̀rọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-