Publicidade

Isaías 64

1 Ìwọ ìbá fa ̀run ya o sọ̀kalẹ̀ ,

àwọn òkè ńlá yóò fi wárìrì níwájú rẹ!

2 Gẹ́gẹ́ ìgbà iná ̀ka igi

ó omi ó ,

sọ̀kalẹ̀ orúkọ rẹ le di mọ̀ fún àwọn ̀rẹ

o jẹ́ àwọn orílẹ̀-èdè ó wárìrì níwájú rẹ!

3 Nítorí nígbà o ṣe àwọn ohun ̀àwa nírètí,

o sọ̀kalẹ̀ , àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀.

4 Láti ìgbà àtijọ́ ẹni ó gbọ́

etí kan ó gbọ́ ,

ojú ó ì Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn rẹ,

ó máa ń ṣe nǹkan lórúkọ àwọn ó dúró é.

5 Ìwọ a máa fún ìrànlọ́wọ́ àwọn wọn

ń fi ayọ̀ ṣe ohun tọ́,

ó rántí ̀rẹ.

Ṣùgbọ́n nígbà a bẹ̀rẹ̀ dẹ́ṣẹ̀ wọn,

inú .

Báwo ni a ó ṣe gbà ?

6 Gbogbo wa ti dàbí ẹnìkan ó jẹ́ aláìmọ́,

gbogbo òdodo wa dàbí èkísà ẹlẹ́gbin;

gbogbo wa kákò ewé,

àti afẹ́fẹ́, ̀ṣẹ̀ wa ti gbá wa lọ kúrò.

7 Ẹnikẹ́ni pe orúkọ rẹ

tàbí ó gbìyànjú láti ́ ;

nítorí ìwọ ti fi ojú rẹ pamọ́ fún wa

ó jẹ́ àwa ṣòfò dànù nítorí àwọn ̀ṣẹ̀ wa.

8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa.

Àwa ni amọ̀, ìwọ ni amọ̀kòkò;

gbogbo wa jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

9 ṣe bínú kọjá ààlà, ìwọ Olúwa,

ṣe rántí gbogbo ̀ṣẹ̀ wa títí láé.

Jọ̀wọ́, bojú , ni a gbàdúrà,

nítorí ènìyàn rẹ ni gbogbo wa.

10 Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀;

Sioni pàápàá di aṣálẹ̀, Jerusalẹmu di ahoro.

11 Tẹmpili mímọ́ ológo wa, níbi àwọn baba wa ti yìn ́,

ni a ti fi iná sun,

àti ohun gbogbo í ṣe ìṣúra wa ti dahoro.

12 Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí, Olúwa, ìwọ ó ha tún fi ara rẹ pamọ́ ?

Ìwọ ó ha dákẹ́ o fìyà jẹ kọjá ààlà ?

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-