Publicidade

Isaías 1

1 Ìran Juda àti Jerusalẹmu èyí Isaiah ọmọ Amosi àsìkò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah àwọn ọba Juda.

Ọlọ̀tẹ̀ orílẹ̀-èdè kan

2 Gbọ́ ̀yin ̀run! Fi etí sílẹ̀, ìwọ ayé!

Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀:

"Mo tọ́ àwọn ọmọ dàgbà,

ṣùgbọ́n wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ mi.

3 Màlúù mọ olówó rẹ̀,

kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mọ ibùjẹ olówó rẹ̀,

ṣùgbọ́n Israẹli mọ̀,

òye àwọn ènìyàn mi."

4 Á à! Orílẹ̀-èdè ẹlẹ́ṣẹ̀,

àwọn ènìyàn ̀bi ̀ṣẹ̀ ń pa lẹ́,

ìran àwọn aṣebi,

àwọn ọmọ ti di aṣèbàjẹ́!

Wọn ti kọ Olúwa sílẹ̀

wọn ti gan Ẹni Mímọ́ Israẹli,

wọn ti kẹ̀yìn i.

5 Èéṣe a ó fi tún yín mọ́?

Èéṣe ò dẹ́kun ̀tẹ̀ ṣíṣe?

Gbogbo orí yín jẹ́ kìkì ọgbẹ́,

gbogbo ọkàn yín ti pòruurù.

6 Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín àtàrí yín

àlàáfíà rárá,

àyàfi ọgbẹ́ òun ìfarapa

àti ojú egbò,

a kúrò tàbí á tàbí a kùn ún òróró.

7 Orílẹ̀-èdè yín dahoro,

a dáná sun àwọn ìlú yín,

oko yín ni àwọn àjèjì ti jẹ run

lójú ara yín náà,

ni gbogbo rẹ̀ ṣòfò èyí

àwọn àjèjì borí rẹ̀.

8 Ọmọbìnrin Sioni ni a fi sílẹ̀

gẹ́gẹ́ àtíbàbà nínú ọgbà àjàrà,

gẹ́gẹ́ abà nínú oko ̀gúnsí,

àti ìlú a .

9 Àyàfi Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ṣẹ́ díẹ̀ fún ,

a ò ti Sodomu,

a ò ti dàbí Gomorra.

10 Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa,

̀yin aláṣẹ Sodomu,

tẹ́òfin Ọlọ́run wa,

̀yin ènìyàn Gomorra!

11 "̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín

kín ni ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín jásí fún mi?" ni Olúwa .

"Mo ti ànító àti àníṣẹ́ẹbọ sísun

ti àgbò àti ̀ẹran àbọ́pa,

Èmi inú dídùn

nínú ̀jẹ̀ akọ màlúù, ti àgùntàn àti ti òbúkọ.

12 Nígbà farahàn níwájú mi,

ta ni ó béèrè èyí lọ́wọ́ yín,

gìrì gìrì ẹsẹ̀ nínú àgbàlá mi?

13 ọrẹ asán mọ́!

Ìríra ni tùràrí yín jásí fún mi,

oṣù tuntun àti ọjọ́ ìsinmi àti àwọn àpéjọ,

Èmi faradà á, ̀ṣẹ̀ ni àpéjọ yín wọ̀nyí.

14 Ayẹyẹ oṣù tuntun yín àti àjọ̀dún a yàn,

ni ọkàn mi kórìíra.

Wọ́n ti di àjàgà mi ọrùn,

Ó mi láti fi ara wọ́n.

15 Nígbà tẹ́ ọwọ́ yín sókè ni àdúrà,

Èmi yóò fi ojú mi pamọ́ fún un yín,

kódà gba ̀pọ̀lọpọ̀ àdúrà,

Èmi ni tẹ́i.

"Ọwọ́ yín kún fún ̀jẹ̀.

16 "Wẹ̀ jẹ́ ara yín mọ́.

ìwà ibi yín kúrò níwájú mi!

Dáwọ́ àìṣedéédéé dúró,

17 kọ́ láti ṣe rere!

ìdájọ́ òtítọ́,

tu àwọn a ń pọ́n lójú nínú.

Ṣàtìlẹyìn fún ̀tọ́ aláìní baba,

gbà ẹjọ́ opó .

18 "ìsinsin yìí, jẹ́ a jọ ṣàṣàrò,"

ni Olúwa .

"̀ṣẹ̀ yín osùn,

wọn ó funfun i yìnyín,

wọn pọ́n ̀jẹ̀,

wọn ó dàbí ̀gbọ̀n òwú.

19 ̀yin fẹ́, gbọ́rọ̀,

̀yin yóò jẹ ojúlówó adùn ilẹ̀ náà.

20 Ṣùgbọ́n kọ̀ ṣọ̀tẹ̀,

idà ni a ó fi pa yín run."

Nítorí ẹnu Olúwa la ti sọ ́.

21 Wo ìlú òtítọ́ ṣe di àgbèrè!

Ó ti kún fún ìdájọ́ òtítọ́ nígbà kan ,

òdodo ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀ ,

ṣùgbọ́n báyìí àwọn apànìyàn!

22 Fàdákà rẹ ti di ìpẹ́pẹ́,

ààyò wáìnì rẹ la ti bu omi .

23 Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn aláṣẹ yín,

akẹgbẹ́ àwọn olè,

gbogbo wọn fẹ́ràn àbẹ̀tẹ́lẹ̀

wọ́n ń ̀bùn kiri.

Wọ́n í ṣàtìlẹyìn fún ̀tọ́ aláìní baba,

ẹjọ́ opó í í iwájú wọn.

24 Nítorí náà ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

alágbára kan ṣoṣo Israẹli sọ :

"Á à! Èmi yóò ìfọ̀kànbalẹ̀ lórí àwọn ̀mi

n ó gbẹ̀san lára àwọn ̀mi.

25 Èmi yóò pa ọwọ́ mi ,

èmi ó ku ìpẹ́pẹ́ rẹ dànù,

n ó gbogbo ìdọ̀rẹ kúrò.

26 Èmi yóò àwọn adájọ́ rẹ bọ̀ ipò gẹ́gẹ́ i ti àtijọ́,

àti àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀ i ti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀.

Lẹ́yìn náà ni a ó ìlú òdodo, ìlú òtítọ́."

27 A ó fi ìdájọ́ òtítọ́ ra Sioni padà,

àti àwọn ó ronúpìwàdà pẹ̀òdodo.

28 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni a ó parun.

Àwọn ó kọ Olúwa sílẹ̀ ni yóò ṣègbé.

29 "Ojú yóò yín nítorí igi óákù mímọ́

èyí inú dídùn ,

a ó kàn yín lábùkù nítorí àwọn ọgbà yìí

ti yàn fúnra yín.

30 ó dàbí igi óákù ewé rẹ̀ ti rọ,

ọgbà omi.

31 Alágbára ọkùnrin náà yóò dàbí ohun ìdáná,

iṣẹ́ rẹ̀ ̀ṣẹ́-iná,

àwọn méjèèjì ni yóò jóná papọ̀,

láìsí ẹni yóò pa iná yìí."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-