Publicidade

Isaías 27

Ìdáǹdè Israẹli

1 ọjọ́ náà,

Olúwa yóò fi idà rẹ̀ jẹ ni

idà rẹ̀ a iná ó tóbi ó lágbára

Lefitani ejò ń yọ̀ tẹ̀̀rẹ̀ n ,

Lefitani ejò ń lọ́ bìrìkìtì;

Òun yóò pa ̀búburú inú Òkun náà.

2 ọjọ́ náà,

"Kọrin nípa ọgbà àjàrà eléso kan.

3 Èmi Olúwa ń bojútó o,

Èmi ó bomirin ín láti ìgbàdégbà.

Èmi ó ṣọ́ tọ̀sán tòru

ẹnikẹ́ni ba à pa á lára.

4 Inú mi.

̀gún àti ̀wọ̀n dojú ìjà kọ !

Èmi yóò dìde wọn ogun,

Èmi yóò dáná sun gbogbo wọn.

5 bẹ́̀ kọ́, jẹ́ wọn sọ́dọ̀ mi fún ààbò;

jẹ́ wọ́n àlàáfíà pẹ̀mi,

bẹ́̀ ni, jẹ́ wọn àlàáfíà pẹ̀mi."

6 ọjọ́ iwájú Jakọbu yóò ta gbòǹgbò,

Israẹli yóò tanná yóò rudi

èso rẹ̀ yóò kún gbogbo ayé.

7 Ǹjẹ́ Olúwa ti ú

gẹ́gẹ́ ó ti lu àwọn ó ú bolẹ̀?

Ǹjẹ́ a ti pa á

gẹ́gẹ́ a ti pa àwọn ó pa á?

8 Nípa ogun jíjà àti ìjìyà ti o le ni ó

fi dojúkọ ́

pẹ̀ìjì gbígbóná ni ó e jáde,

gẹ́gẹ́ ọjọ́ afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn fẹ́.

9 Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe

fún ̀ṣẹ̀ Jakọbu,

èyí ni yóò jẹ́ èso kíkún ti

ìmúkúrò ̀ṣẹ̀ rẹ.

Nígbà ó àwọn òkúta pẹpẹ

dàbí òkúta ẹfun a fọ́ wẹ́wẹ́,

yóò ère Aṣerah tàbí pẹpẹ tùràrí

yóò ìdúró.

10 Ìlú olódi náà ti dahoro,

ibùdó ìkọ̀sílẹ̀, a kọ̀

gẹ́gẹ́ aginjù;

níbẹ̀ ni àwọn ọmọ màlúù ti ń jẹ oko

níbẹ̀ ni wọn ń sùn sílẹ̀;

wọn jẹ gbogbo ̀ka rẹ̀ tán.

11 Nígbà àwọn ̀ka rẹ̀ rọ, a ó ya wọn dànù

àwọn obìnrin , wọ́n fi wọ́n dáná

nítorí aláìlóye ènìyàn ni wọn jẹ́,

nítorí náà ni ẹni ó wọn yóò ṣàánú fún wọn;

bẹ́̀ ni ẹni ó mọ wọn yóò fi ojúrere wọ́n.

12 ọjọ́ náà Olúwa yóò oore láti ìṣàn omi odo Eufurate títí Wadi ti Ejibiti, àti ìwọ, ìwọ ọmọ Israẹli, ni a ó kójọ ̀kọ̀̀kan. 13 Àti ọjọ́ náà, a ó fun fèrè ńlá kan. Gbogbo àwọn ń ṣègbé lọ Asiria àti àwọn ń ṣe àtìpó Ejibiti yóò sin Olúwa òkè mímọ́ Jerusalẹmu.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-