Publicidade

Isaías 31

Ègbé ni fún àwọn o gbẹ́kẹ̀Ejibiti

1 Ègbé ni fún àwọn ó sọ̀kalẹ̀ lọ

Ejibiti fún ìrànlọ́wọ́,

wọn gbẹ́kẹ̀ẹṣin

wọ́n fi ìgbẹ́kẹ̀wọn ̀pọ̀lọpọ̀ kẹ̀kẹ́-ẹṣin wọn

àti agbára ńlá àwọn ẹlẹ́ṣin wọn,

ṣùgbọ́n tiwọn bojú wo Ẹni Mímọ́ Israẹli n ,

tàbí wọn ìrànlọ́wọ́ lọ́dọ̀ Olúwa.

2 Síbẹ̀síbẹ̀ òun pẹ̀jẹ́ ọlọ́gbọ́n ó ìparun ;

òun í ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ.

Òun yóò dìde ilé àwọn ìkà,

àti àwọn ń ṣe ìrànlọ́wọ́ fún aṣebi.

3 Ṣùgbọ́n ènìyàn lásán ni àwọn ará Ejibiti

wọn í ṣe Ọlọ́run;

ẹran-ara ni àwọn ẹṣin wọn, í ṣe ̀.

Nígbà Olúwa na ọwọ́ rẹ̀ jáde,

ẹni náà ó ń ṣèrànwọ́ yóò kọsẹ̀,

ẹni náà à ń ràn lọ́wọ́ yóò ṣubú;

àwọn méjèèjì yóò jùmọ̀ parun.

4 Èyí ni ohun Olúwa sọ fún mi:

"Gẹ́gẹ́ i kìnnìún ti í

àní kìnnìún ńlá lórí ẹran ọdẹ rẹ̀

a tilẹ̀ ẹgbẹ́ àwọn olùṣọ́-àgùntàn

a wọ́n papọ̀ láti kojú rẹ̀,

̀á pẹ̀igbe wọn

akitiyan wọn i lọ́wọ́

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò sọ̀kalẹ̀

láti jagun lórí òkè Sioni àti lórí ibi gíga rẹ̀.

5 Gẹ́gẹ́ àwọn ẹyẹ ti ń rábàbà lókè

Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bo Jerusalẹmu,

Òun yóò dáàbò ó, yóò u sílẹ̀

Òun yóò e kọjá yóò gbà á sílẹ̀."

6 padà sọ́dọ̀ ẹni ti ṣọ̀tẹ̀ gidigidi, ̀yin ọmọ Israẹli.

7 Nítorí ọjọ́ náà, ẹnìkọ̀̀kan yín yóò kọ àwọn ère fàdákà àti wúrà ọwọ́ ̀ṣẹ̀ yín ti ṣe.

8 "Asiria yóò ṣubú lọ́wọ́ idà kan ti ọwọ́ ènìyàn ;

idà í ṣe ti ̀alààyè ni yóò pa wọ́n.

Wọn yóò níwájú idà náà

àti àwọn ọmọkùnrin wọn ni a ó fún iṣẹ́ ipá ṣe.

9 Àpáta rẹ yóò kọjá lọ fún ̀;

àwọn olórí rẹ yóò bẹ̀asia náà,"

ni Olúwa ,

ẹni iná rẹ̀ ń bẹ Sioni,

ẹni ìléru rẹ̀ Jerusalẹmu.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-