Publicidade

Isaías 33

Ìpọ́njú àti ìrànlọ́wọ́

1 Ègbé ni fún , ìwọ apanirun,

ìwọ a ì parun!

Ègbé ni fún , ìwọ ̀dàlẹ̀,

ìwọ a ì ́!

Nígbà o dẹ́kun à ń pa ni run;

a ó pa ìwọ náà run,

nígbà o dẹ́kun à ń dani,

a ó da ìwọ náà.

2 Olúwa ṣàánú fún wa

àwa ń ṣàfẹ́i rẹ.

Máa jẹ́ agbára wa òròòwúrọ̀

ìgbàlà wa àsìkò ìpọ́njú.

3 ìkérara ohùn rẹ, àwọn ènìyàn ,

nígbà o dìde sókè, àwọn orílẹ̀-èdè fọ́nká.

4 Ìkógun rẹ, ìwọ orílẹ̀-èdè ni a kórè

gẹ́gẹ́ i ti ̀dọ́ eṣú;

gẹ́gẹ́ àkójọpọ̀ eṣú, àwọn ènìyàn wọ ibẹ̀.

5 A gbé Olúwa ga, nítorí ó ń gbé ibi gíga,

Òun yóò kún Sioni pẹ̀̀tọ́ àti òdodo.

6 Òun yóò jẹ́ ìpìlẹ̀ ó dájú fún àkókò rẹ

ibùjókòó ìgbàlà kíkún àti ọgbọ́n òun ìmọ̀;

ìbẹ̀Olúwa ni kọ́kọ́rọ́ ìṣúra yìí.

7 ó, àwọn onígboyà ọkùnrin wọn pohùnréré

ẹkún òpópónà;

àwọn ikọ̀ àlàáfíà sọkún kíkorò.

8 Àwọn ojú ̀ńlá ni a ṣá ,

arìnrìn-àjò kankan ojú ̀.

A ti ba àdéhùn jẹ́,

a kẹ́gàn àwọn ẹlẹ́rìí,

a bu ọlá fún ẹnikẹ́ni.

9 Ilẹ̀ ṣọ̀fọ̀ ó ṣòfò dànù,

ojú ti Lebanoni ó

Ṣaroni dàbí aginjù,

àti Baṣani òun Karmeli rẹ àwọn èwe wọn.

10 "ìsinsin yìí ni èmi yóò dìde," ni Olúwa .

"ìsinsin yìí ni a ó gbé mi ga,

ìsinsin yìí ni a ó gbé mi sókè.

11 Ìwọ lóyún ìyàngbò,

o koríko;

èémí yín iná yóò jẹ yín run.

12 A ó àwọn ènìyàn run eérú;

igbó ̀gún a la ó dáná wọn."

13 Ìwọ ó lọ́jíjìn, gbọ́ ohun mo ti ṣe;

ìwọ ò ń bẹ nítòsí, jẹ́rìí agbára mi!

14 ̀ba àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ Sioni;

ìwárìrì àwọn gba Ọlọ́run gbọ́:

"Ta ni nínú wa lólè gbé pẹ̀iná ajónirun?

Ta ni nínú wa lólè gbé pẹ̀iná àìnípẹ̀kun?"

15 Ẹni ó ń rìn lódodo

ó ń sọ ohun ó tọ́,

ó kọ èrè ó ti ibi ìlọ́nilọ́wọ́gbà ,

ó pa ọwọ́ rẹ̀ mọ́ kúrò nínú gbígba àbẹ̀tẹ́lẹ̀,

ó di etí rẹ̀ ̀tẹ̀ láti pànìyàn

ó di ojú rẹ̀ à ti pète ibi,

16 Òun náà yóò gbé ibi gíga,

ibi ààbò rẹ̀ yóò jẹ́ òkè ńlá olódi.

A ó oúnjẹ fún un,

omi rẹ̀ yóò dájú.

17 Ojú rẹ yóò ọba nínú ẹwà rẹ̀

yóò ilẹ̀ kan ó tẹ́ lọ rẹrẹẹrẹ.

18 Nínú èrò rẹ ìwọ yóò rántí ̀rẹ àtẹ̀yìnwá:

"Níbo ni ̀àgbà náà ?

Níbo ni ẹni ń gba owó òde ?

Níbo ni òṣìṣẹ́ ti ó ń mójútó ilé ìṣọ́ ?"

19 Ìwọ yóò àwọn agbéraga ènìyàn mọ́,

àwọn ènìyàn èdè wọn fi ara sin,

pẹ̀ahọ́n ó ṣàjèjì ni.

20 Gbójú sókè Sioni, ìlú àjọ̀dún wa,

ojú rẹ yóò Jerusalẹmu,

ibùgbé àlàáfíà n , àgọ́ a padà;

àwọn òpó rẹ̀ ni a yóò fàtu

tàbí èyíkéyìí nínú okùn rẹ̀ .

21 Níbẹ̀ ni Olúwa yóò ti jẹ́ alágbára kan fún wa.

Yóò dàbí ibi àwọn odò ńlá ńlá àti odò kéékèèké.

yóò ọkọ̀ ojú omi pẹ̀yóò kọjá lórí i wọn,

ọkọ̀ ojú omi ńlá ni a yóò lórí wọn.

22 Nítorí Olúwa ni onídàájọ́ wa,

Olúwa ni onídàájọ́ wa,

Olúwa òun ni ọba wa;

òun ni ẹni yóò gbà .

23 Gbogbo okùn rẹ ni ó ti dẹ̀:

Ìgbókùnró fìdímúlẹ̀,

wọn taṣọ agbọ́kọ̀rìn,

lẹ́yìn náà, ̀pọ̀lọpọ̀ ìkógun ni a ó pín

àní arọ pẹ̀yóò ru ìkógun lọ.

24 ẹnikẹ́ni ó ń gbé Sioni yóò , "Ara mi ,"

a ó dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn ń gbé ibẹ̀ wọ́n.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-