Publicidade

Isaías 51

Ìgbàlà ayérayé fún Sioni

1 "Tẹ́mi, ̀yin ó ń lépa òdodo

àti ̀yin ń Olúwa.

Wo àpáta, nínú èyí a ti yín jáde

àti ihò òkúta níbi a ti gbẹ́ yín jáde;

2 wo Abrahamu baba yín,

àti Sara, ẹni i yín.

Nígbà mo é, òun nìkan ni,

Èmi bùkún un, mo ṣọ́ di ̀pọ̀lọpọ̀.

3 Dájúdájú, Olúwa yóò tu Sioni nínú

yóò bojú àánú wo gbogbo ahoro rẹ̀;

Òun yóò sọ gbogbo aṣálẹ̀ rẹ̀ di Edeni,

àti aṣálẹ̀ rẹ̀ yóò ọgbà Olúwa.

Ayọ̀ àti inú dídùn ni a ó nínú rẹ̀,

ọpẹ́ àti ariwo orín kíkọ.

4 "Tẹ́mi, ̀yin ènìyàn mi;

gbọ́ tèmi, ̀yin orílẹ̀-èdè mi.

Òfin yóò ti ̀dọ̀ mi jáde ;

ìdájọ́ mi yóò di ìmọ́lẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè.

5 Òdodo mi ń bọ̀ kíkankíkan,

ìgbàlà mi ń bọ̀ lójú ̀,

àti apá mi yóò ìdájọ́

àwọn orílẹ̀-èdè.

Àwọn erékùṣù yóò

wọn yóò dúró ìrètí fún apá mi.

6 Gbé ojú rẹ sókè àwọn ̀run,

wo ilẹ̀ ìsàlẹ̀ ilẹ̀;

àwọn ̀run yóò pòórá èéfín,

ilẹ̀ yóò gbó ̀

àwọn olùgbé inú rẹ̀ yóò gẹ́gẹ́ àwọn eṣinṣin.

Ṣùgbọ́n ìgbàlà mi yóò títí láé,

òdodo mi yóò yẹ̀ láé.

7 "gbọ́ mi, ̀yin ó mọ ohun òtítọ́,

̀yin ènìyàn ó òfin mi àyà yín.

ṣe bẹ̀̀gàn àwọn ènìyàn

tàbí ̀èébú wọn a yín láyà.

8 Nítorí kòkòrò yóò wọn aṣọ,

ìdin yóò wọn jẹ ̀gbọ̀n òwú.

Ṣùgbọ́n òdodo mi yóò títí ayérayé,

àti ìgbàlà mi láti ìrandíran."

9 Dìde, dìde! o wọ ara rẹ agbára

ìwọ apá Olúwa;

dìde gẹ́gẹ́ i ti ọjọ́ ìgbà n ,

àti gẹ́gẹ́ i ti ìran àtijọ́.

Ìwọ kọ́ lo Rahabu wẹ́wẹ́

o fa ̀búburú ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ?

10 Ìwọ kọ́ ni ó gbẹ omi Òkun

àti àwọn omi inú ̀gbun,

o ṣe ̀nínú ìsàlẹ̀ Òkun

bẹ́̀ àwọn ẹni ìràpadà yóò fi le á kọjá?

11 Àwọn ẹni ìràpadà Olúwa yóò padà .

Wọn yóò wọ Sioni pẹ̀orin kíkọ;

ayọ̀ ayérayé ni yóò bo orí wọn.

Ayọ̀ àti inú dídùn yóò wọn

ìbànújẹ́ àti ìtìjú yóò kúrò.

12 "Èmi, àní Èmi, èmi ni ẹni ó ́ nínú.

Ta ni ́ o fi ń bẹ̀ènìyàn ẹlẹ́ran ara,

àti ọmọ ènìyàn, ó jẹ́ koríko lásán,

13 ìwọ gbàgbé Olúwa ẹlẹ́dàá rẹ,

ẹni ó ta àwọn ̀run

ó fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,

ń gbé nínú ìpayà lójoojúmọ́

nítorí ìbínú àwọn aninilára,

wọ́n gbẹ́kẹ̀ìpanirun?

Nítorí ibo ni ìbínú àwọn aninilára gbé ?

14 Àwọn ẹlẹ́wọ̀n ń ṣojo la ó sílẹ̀ àìpẹ́ jọjọ

wọn sínú túbú wọn,

bẹ́̀ ni wọn ṣe aláìní àkàrà.

15 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ó ń ru Òkun sókè bẹ́̀

ìgbì rẹ̀ fi ń pariwo

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

16 Mo ti fi ̀rọ̀ mi ẹnu rẹ

mo ti fi òjìji ọwọ́ mi ́,

Èmi mo tẹ́ àwọn ̀run ààyè rẹ̀,

ẹni ó fi ìpìlẹ̀ ilẹ̀ ayé lélẹ̀,

àti ẹni ó sọ fún Sioni ,

̀yin ni ènìyàn mi.’ "

Ago ìbínú Olúwa

17 , !

Gbéra nílẹ̀ ìwọ Jerusalẹmu,

ìwọ o ti mu láti ọwọ́ Olúwa

ago ìbínú rẹ̀,

ìwọ o ti á mu gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀

ó n ènìyàn ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.

18 Nínú gbogbo ọmọ ó

̀kankan ó tọ́ ṣọ́

nínú gbogbo ọmọ ó tọ́

èyí ó le á lọ́wọ́.

19 Àjálù ìlọ́po ìlọ́po yìí ti

ta ni yóò ́ nínú?

Ìparun àti ìdahoro, ìyàn àti idà

ta ni pẹ̀lọ́kàn?

20 Àwọn ọmọkùnrin rẹ ti dákú;

wọ́n sùn oríta gbogbo òpópónà,

gẹ́gẹ́ etu a mọ́àwọ̀n.

Ìbínú Olúwa ti kún inú wọn fọ́fọ́

àti ìbáwí Ọlọ́run yín.

21 Nítorí náà gbọ́ èyí, ̀yin a ti ṣẹ́ níṣẹ̀́,

ọtí ń pa, ṣùgbọ́n í ṣe fún wáìnì.

22 Ohun Olúwa Olódùmarè yín nìyìí,

Ọlọ́run rẹ, ẹni ó ń pa ènìyàn rẹ̀ mọ́,

"Kíyèsi i, mo ti un kúrò ọwọ́ rẹ

ago ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n;

láti inú ago náà, ̀kún ìbínú mi,

ni ìwọ yóò mu mọ́.

23 Èmi yóò fi àwọn apọ́nilójú rẹ lọ́wọ́,

àwọn ó fún ,

Dọ̀bálẹ̀, bẹ́̀ a ó fi máa rìn lórí rẹ.

Ìwọ náà ṣe ̀yìn rẹ gẹ́gẹ́ ilẹ̀

gẹ́gẹ́ òpópónà láti máa rìn lórí i rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-