Publicidade

Isaías 6

Ìpè iṣẹ́ ìránṣẹ́ Isaiah

1 ọdún ọba Ussiah , mo Olúwa ó jókòó lórí ìtẹ́ ó ga a gbé sókè, ìṣẹ́aṣọ ìgúnwà rẹ̀ kún inú tẹmpili. 2 Àwọn Serafu òkè rẹ̀, ̀kọ̀̀kan wọn ìyẹ́ mẹ́, wọ́n fi ìyẹ́ méjì bo ojú wọn, wọ́n fi méjì bo ẹsẹ̀ wọn, wọ́n ń fi méjì . 3 Wọ́n ń kọ ara wọn ,

"Mímọ́, mímọ́, mímọ́ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun

gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀."

4 Nípa ìró ohùn un wọn, òpó ìlẹ̀kùn àti gbogbo ògiri ilé náà tìtì, gbogbo inú tẹmpili kún fún èéfín.

5 Mo kígbe , "Ègbé ni fún mi! Mo ti gbé!" Nítorí mo jẹ́ ènìyàn aláìmọ́ ètè, mo ń gbé láàrín àwọn ènìyàn aláìmọ́ ètè, ojú mi ti ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun jùlọ.

6 Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn Serafu wọ̀nyí ̀dọ̀ mi pẹ̀̀yín iná ọwọ́ rẹ̀, èyí ó ti fi ̀orí pẹpẹ. 7 Èyí ni ó fi kàn ẹnu ó , "ó, èyí ti kan ètè rẹ; a ti ̀bi rẹ kúrò, a ti wẹ ̀ṣẹ̀ rẹ ."

8 Nígbà náà ni mo gbọ́ ohùn Olúwa , "Ta ni èmi yóò rán? Ta ni yóò lọ fún wa?"

Nígbà náà ni èmi , "Èmi nìyí, rán mi!"

9 Òun , "Tọ àwọn ènìyàn yìí lọ o fún wọn ,

" gbígbọ́ ̀yin yóò gbọ́, yóò e yín;

̀yin yóò ri, ̀yin yóò mọ òye.

10 àyà àwọn ènìyàn wọ̀nyí yigbì,

etí wọn ó wúwo,

o dìwọ́n ojú.

wọn ó ba fi ojú wọn ríran,

wọn ó ba fi etí wọn gbọ́rọ̀,

òye ó ba ọkàn wọn,

wọn ó ba yípadà

a ba wọn ara ."

11 Nígbà náà ni mo , "Báwo ni yóò ti pẹ́ Olúwa?"

Òun dáhùn :

"Títí àwọn ìlú ńlá yóò fi dahoro,

láìsí olùgbé nínú rẹ̀ mọ́,

títí àwọn ilé yóò fi láìsí ènìyàn,

títí ilẹ̀ yóò fi dahoro pátápátá.

12 Títí Olúwa yóò fi rán gbogbo wọn jìnnà réré

ilẹ̀ náà di ìkọ̀sílẹ̀ pátápátá.

13 ó tilẹ̀ jẹ́ ìdámẹ́wàá ṣẹ́lórí ilẹ̀ náà,

yóò tún pàpà padà di rírun.

Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ igi tẹrẹbinti àti igi óákù,

ti í fi kùkùté sílẹ̀ nígbà a wọn lulẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni irúgbìn mímọ́ náà yóò di kùkùté ilẹ̀ náà."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-