Publicidade

Isaías 60

Ògo Sioni

1 "Dìde, tànmọ́lẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti ,

ògo Olúwa ràdàbò ́.

2 Kíyèsi i, òkùnkùn bo ilẹ̀ ayé

òkùnkùn biribiri lórí àwọn ènìyàn,

ṣùgbọ́n Olúwa ràn ́

ògo rẹ̀ farahàn lórí i rẹ.

3 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò ìmọ́lẹ̀ rẹ,

àti àwọn ọba ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ rẹ.

4 "Gbé ojú rẹ sókè, o .

Gbogbo wọn ṣa ara jọ pọ̀, wọ́n sọ́dọ̀ rẹ;

àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin yóò láti ̀jíjìn,

àwọn ọmọ rẹ obìnrin ni a ó tọ́̀gbẹ́ rẹ.

5 Nígbà náà ni ìwọ yóò ojú rẹ yóò máa dán,

ọkàn rẹ , kún fún ayọ̀;

ọrọ̀ inú Òkun ni a ó sọ́dọ̀ rẹ,

̀dọ̀ rẹ ni ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yóò .

6 ̀wọ́ ìbákasẹ yóò bo gbogbo ilẹ̀ rẹ,

àwọn ̀dọ́ ìbákasẹ Midiani àti Efani.

Àti gbogbo wọn láti Ṣeba yóò ,

wọn yóò wúrà àti tùràrí lọ́wọ́

wọn yóò máa kéde ìyìn Olúwa.

7 Gbogbo agbo ẹran ìlú Kedari ni a ó kójọ sọ́dọ̀ rẹ,

àwọn àgbò ti Nebaioti yóò sìn ́;

wọn yóò jẹ́ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà lórí i pẹpẹ mi,

bẹ́̀ ni n ó ṣe tẹmpili ògo mi lọ́ṣọ̀́.

8 "Ta ni àwọn wọ̀nyí ń lọ i kurukuru,

gẹ́gẹ́ àwọn àdàbà ìtẹ́ wọn?

9 Lóòtítọ́ àwọn erékùṣù bojú ;

ìṣíwájú ni àwọn ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi;

àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti ̀jíjìn,

pẹ̀fàdákà àti wúrà wọn,

fún ti ọlá Olúwa Ọlọ́run rẹ,

Ẹni Mímọ́ Israẹli,

nítorí òun ti fi ohun dídára ṣe ó lọ́ṣọ̀́.

10 "Àwọn àjèjì yóò tún ògiri rẹ mọ

àwọn ọba wọn yóò sìn ́.

ó tilẹ̀ jẹ́ ìbínú ni mo ́,

àánú èmi yóò ṣe inú rere .

11 Gbogbo ẹnu-bodè rẹ ni yóò ṣíṣí sílẹ̀,

a yóò wọ́n ̀sán àti òru,

bẹ́̀ àwọn ọkùnrin yóò le è

ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè

àwọn ọba wọn yóò ṣáájú ̀wọ̀̀wọ́ ìṣẹ́gun.

12 Nítorí orílẹ̀-èdè tàbí ilẹ̀ ọba yóò sìn ́ ni yóò parun;

pátápátá ni yóò dahoro.

13 "Ògo Lebanoni yóò ̀dọ̀ rẹ,

igi junifa, firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀,

láti bu ọlá fún ilé ìsìn mi;

àti èmi yóò ṣe ibi ẹsẹ̀ mi lógo.

14 Àwọn ̀dọ́mọkùnrin àwọn apọ́nilójú rẹ yóò

foríbalẹ̀ fún ;

gbogbo àwọn ó ti kẹ́gàn rẹ ni wọn yóò tẹríba níwájú rẹ

wọn yóò ́ ìlú Olúwa,

Sioni ti Ẹni Mímọ́ Israẹli.

15 "ó tilẹ̀ jẹ́ a ti kórìíra rẹ, a kọ̀ ́ sílẹ̀,

láìsí ẹnìkan ó ń gba ̀dọ̀ rẹ kọjá,

Èmi yóò ṣe ́ ìṣògo ayérayé

àti ayọ̀ àtìrandíran.

16 Ìwọ yóò mu wàrà gbogbo orílẹ̀-èdè

a ó fun ́ ni ọmú àwọn ọba.

Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ , Èmi Olúwa,

èmi ni Olùgbàlà rẹ,

Olùdáǹdè rẹ, Alágbára ti Jakọbu.

17 Dípò idẹ, èmi ó wúrà fún ,

dípò fàdákà èmi ó irin . Dípò igi yóò idẹ fún ,

àti irin dípò òkúta.

Èmi yóò fi àlàáfíà ṣe àwọn ìjòyè rẹ

àti òdodo gẹ́gẹ́ alákòóso rẹ.

18 A yóò gbọ́ nípa rògbòdìyàn ilẹ̀ rẹ mọ́,

tàbí ìdahoro àti ìparun nínú agbègbè rẹ,

ṣùgbọ́n ìwọ yóò pe ògiri rẹ ìgbàlà

àti àwọn ẹnu-bodè rẹ ìyìn.

19 Òòrùn yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ̀sán mọ́,

tàbí ìtànṣán òṣùpá tún ràn mọ́,

nítorí Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ayérayé,

àti Ọlọ́run rẹ yóò jẹ́ ògo rẹ.

20 Òòrùn rẹ yóò wọ̀ mọ́,

àti òṣùpá rẹ yóò wọ òòkùn mọ́;

Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé rẹ,

àti àwọn ọjọ́ arò rẹ yóò dópin.

21 Lẹ́yìn náà ni gbogbo àwọn ènìyàn rẹ yóò di òdodo

àwọn ni yóò jogún ilẹ̀ náà títí ayé.

Àwọn ni irúgbìn mo ti gbìn,

iṣẹ́ ọwọ́ mi,

láti fi ọláńlá mi hàn.

22 Èyí ó kéré nínú yín yóò di ẹgbẹ̀rún (1,000) kan,

èyí ó kéré yóò di orílẹ̀-èdè ńlá.

Èmi ni Olúwa;

àkókò rẹ̀, Èmi yóò ṣe èyí kánkán."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-