Publicidade

Isaías 61

Ọdún ojúrere Olúwa

1 ̀Olúwa Olódùmarè lára mi

nítorí Olúwa ti fi àmì òróró yàn

láti wàásù ìyìnrere fún àwọn tálákà.

Ó ti rán mi láti ṣe àwòtán oníròbìnújẹ́

láti kéde ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn

àti ìtúsílẹ̀ kúrò nínú òkùnkùn fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n,

2 láti kéde ọdún ojúrere Olúwa

àti ọjọ́ ̀san ti Ọlọ́run wa,

láti tu àwọn ń ṣọ̀fọ̀ nínú,

3 àti láti pèsè fún àwọn inú wọn bàjẹ́ Sioni

láti wọn ládé ẹwà dípò eérú,

òróró ayọ̀ dípò ̀fọ̀,

àti aṣọ ìyìn dípò ìpòrúru ọkàn.

A ó wọ́n igi óákù òdodo,

irúgbìn Olúwa

láti fi ọláńlá rẹ̀ hàn.

4 Wọn yóò tún àwọn ahoro àtijọ́ kọ́

wọn yóò àwọn ibi ìparun àtijọ́-tijọ́ náà bọ̀ sípò;

wọn yóò àwọn ahoro ìlú náà padà

a ti parun láti ìrandíran sẹ́yìn.

5 Àwọn àjèjì ni yóò máa da ̀wọ́ ẹran rẹ;

àwọn àlejò yóò ṣiṣẹ́ nínú oko àti ọgbà àjàrà rẹ.

6 A ó máa yín àlùfáà Olúwa,

a ó yín ìránṣẹ́ Ọlọ́run wa.

ó máa jẹ nínú ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè

àti nínú ọrọ̀ wọn ni ̀yin yóò máa ṣògo.

7 Dípò àbùkù wọn

àwọn ènìyàn mi yóò gba ìlọ́po méjì,

àti dípò àbùkù wọn

wọn yóò yọ̀ nínú ìní wọn;

bẹ́̀ ni wọn yóò jogún ìlọ́po méjì ilẹ̀ wọn,

ayọ̀ ayérayé yóò jẹ́ tiwọn.

8 "Nítorí Èmi, Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òdodo;

mo kórìíra olè jíjà àti ̀ṣẹ̀.

òtítọ́ mi èmi yóò sẹ̀san fún wọn

èmi yóò májẹ̀ayérayé pẹ̀wọn.

9 A ó mọ ìrandíran wọn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

àti àwọn ìran wọn láàrín àwọn ènìyàn.

Gbogbo àwọn ó wọn yóò mọ̀

wọ́n jẹ́ àwọn ènìyàn Olúwa ti bùkún."

10 Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa;

ọkàn mi yọ̀ nínú Ọlọ́run mi.

Nítorí ó ti wọ̀ aṣọ ìgbàlà

ó ṣe lọ́ṣọ̀́ nínú aṣọ òdodo;

gẹ́gẹ́ ọkọ ìyàwó ti ṣe orí rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ àlùfáà,

àti ìyàwó ṣe ń ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀́ pẹ̀ohun ̀ṣọ́.

11 Gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ti í irúgbìn jáde

àti ọgbà ṣe ń irúgbìn dàgbà,

bẹ́̀ ni Olúwa Olódùmarè yóò ṣe òdodo àti ìyìn

ó ru sókè níwájú gbogbo orílẹ̀-èdè.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-