Publicidade

Isaías 65

Ìdájọ́ àti ìgbàlà

1 "Èmi fi ara mi hàn fún àwọn béèrè fún mi;

àwọn mi ni wọ́n mi.

àwọn orílẹ̀-èdè pe orúkọ mi,

ni èmi , Èmi nìyìí, Èmi nìyìí.

2 Gbogbo ọjọ́ ni mo ti nawọ́ mi síta

àwọn ènìyàn ọlọ́rùn líle,

wọn ń rìn lọ́dára,

wọ́n gbára èrò ara wọn

3 àwọn ènìyàn wọ́n mi nínú nígbà gbogbo

lójú ara mi gan an,

wọ́n ń ẹbọ nínú ọgbà

wọ́n ń sun tùràrí lórí i pẹpẹ bíríkì;

4 wọ́n ń jókòó láàrín ibojì

wọ́n ń lo òru wọn nínú ìṣọ́ ìkọ̀kọ̀;

wọ́n ń jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀,

ìkòkò ọbẹ̀ wọn kún fún ẹran àìmọ́;

5 ó , sún mẹ́yìn; sọ́dọ̀ mi,

nítorí mo ti jẹ́ mímọ́ fún un yín!

Àwọn ènìyàn bẹ́̀ jẹ́ èéfín nínú ihò imú mi

iná ń fi gbogbo ọjọ́ .

6 "Kíyèsi i, a ti kọ ́ síwájú mi,

Èmi yóò dákẹ́,

ṣùgbọ́n èmi yóò san án padà lẹ́kùnrẹ́rẹ́;

Èmi yóò san án padà àyà wọn

7 àwọn ̀ṣẹ̀ yín àti tàwọn baba yín,"

ni Olúwa .

"Nítorí wọ́n sun ẹbọ orí òkè ńlá

wọ́n ṣe ̀gbin mi òkè kékeré,

Èmi yóò wọ́n ́n itan wọn

̀kúnrẹ́rẹ́ ̀san ohun gbogbo wọ́n ṣe tẹ́lẹ̀."

8 Báyìí ni Olúwa :

"Gẹ́gẹ́ ìgbà oje tún nínú àpólà àjàrà

àwọn ènìyàn , ṣe á jẹ́,

nítorí ìbùkún ń bẹ nínú rẹ̀,’

bẹ́̀ ni èmi yóò ṣe nítorí ìránṣẹ́ mi;

Èmi yóò pa gbogbo wọn run.

9 Èmi yóò ìrandíran láti ìdílé Jakọbu,

àti láti Juda àwọn yóò jogún òkè ńlá mi wọ̀n-ọn-nì;

àwọn àyànfẹ́ ènìyàn mi yóò jogún wọn,

ibẹ̀ ni àwọn ìránṣẹ́ mi yóò gbé.

10 Ṣaroni yóò di pápá oko fún ̀wọ́ ẹran,

àti àfonífojì Akori yóò di ibi ìsinmi fún agbo ẹran,

fún àwọn ènìyàn mi ó mi.

11 "Ṣùgbọ́n fún ̀yin ó kọ Olúwa sílẹ̀

ó gbàgbé òkè ńlá mímọ́ mi,

ó tẹ́ tábìlì fún Gadi

kún abọ́ pẹ̀ọtí wáìnì fún àtubọ̀tán,

12 Èmi yóò ́ sọ́tọ̀ fún idà,

àti ̀yin yóò bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀ fún àwọn a pa;

nítorí mo , ṣùgbọ́n ̀yin dáhùn.

Mo sọ̀rọ̀ ṣùgbọ́n ̀yin tẹ́sílẹ̀.

̀yin ṣe búburú ojú mi

yan ohun ó lọ́kàn jẹ́."

13 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

"Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò jẹun;

ṣùgbọ́n ebi yóò máa pa ̀yin,

àwọn ìránṣẹ́ mi yóò mu,

ṣùgbọ́n òǹgbẹ yóò máa gbẹ ̀yin;

àwọn ìránṣẹ́ mi yóò ṣe àjọyọ̀,

ṣùgbọ́n a ó dójútì yin.

14 Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò kọrin

láti inú ayọ̀ ọkàn wọn ,

ṣùgbọ́n ̀yin yóò kígbe sókè

láti inú ìrora ọkàn yín

àti ìpohùnréré ìròbìnújẹ́ ọkàn.

15 ̀yin yóò fi orúkọ yín sílẹ̀

fún àwọn àyànfẹ́ mi gẹ́gẹ́ ègún;

Olúwa Olódùmarè yóò pa yín,

ṣùgbọ́n fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ni òun

yóò fún orúkọ mìíràn.

16 Ẹnikẹ́ni ó gbàdúrà ìbùkún ilẹ̀ náà

yóò ṣe é nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́;

Ẹni ó búra ilẹ̀ náà

yóò búra nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́.

Nítorí ìyọnu àtijọ́ yóò di ìgbàgbé

yóò fi ara sin kúrò lójú mi.

Àwọn ọrun tuntun àti ayé tuntun

17 "Kíyèsi i, Èmi yóò

àwọn ̀run tuntun àti ayé tuntun.

A yóò rántí ohun àtẹ̀yìnwá mọ́,

tàbí wọn ọkàn.

18 Ṣùgbọ́n yọ̀ inú yín dùn títí láé

nínú ohun èmi yóò ,

nítorí èmi yóò Jerusalẹmu láti jẹ́ ohun ìdùnnú

àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ohun ayọ̀.

19 Èmi yóò ṣe àjọyọ̀ lórí Jerusalẹmu

n ó inú dídùn nínú àwọn ènìyàn mi;

ariwo ẹkún àti igbe

ni a yóò gbọ́ nínú rẹ̀ mọ́.

20 "Títí láé a yóò gbọ́ nínú rẹ̀

ọmọ ọwọ́ yóò gbé fún ọjọ́ díẹ̀,

tàbí àgbàlagbà yóò lo ọjọ́ ayé rẹ̀ tán;

ẹni ó ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún

ni a ó ̀dọ́mọdé;

ẹni ba le ọgọ́rùn-ún kan

ni a ó ẹni ìfibú.

21 Wọn ò kọ́ ilé, wọn yóò gbé nínú wọn

wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò jẹ èso wọn.

22 Wọn yóò kọ́ ilé fún ẹlòmíràn láti gbé,

tàbí wọn gbìn fún ẹlòmíràn láti jẹ.

Nítorí gẹ́gẹ́ ọjọ́ orí igi kan,

bẹ́̀ ọjọ́ àwọn ènìyàn mi yóò ;

àwọn àyànfẹ́ mi yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́

wọn fún ìgbà pípẹ́.

23 Wọn yóò ṣe iṣẹ́ lásán,

wọn yóò bímọ fún wàhálà;

nítorí wọn yóò jẹ́ àwọn ènìyàn ti Olúwa bùkún fún,

àwọn àti àwọn ìrandíran wọn pẹ̀wọn.

24 wọn , èmi yóò dáhùn;

nígbà wọ́n ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, èmi yóò gbọ́.

25 Ìkookò àti ̀dọ́-àgùntàn yóò jẹun pọ̀,

kìnnìún yóò jẹ koríko gẹ́gẹ́ akọ màlúù,

ṣùgbọ́n erùpẹ̀ ni yóò jẹ́ oúnjẹ ejò.

Wọn yóò pa ni lára tàbí pa ni run

gbogbo òkè mímọ́ mi,"

ni Olúwa .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-