Pular para o conteúdo
Publicidade

Ezequiel 23

Arábìnrin panṣágà méjì

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, obìnrin méjì , ọmọ ìyá kan náà. 3 Wọn ń ṣe panṣágà Ejibiti, wọn ń ṣe panṣágà láti ìgbà èwe wọn. ilẹ̀ yẹn ni wọn ti fi ọwọ́ pa ọyàn wọn, níbẹ̀ ni wọn fọwọ́ pa igbá àyà èwe wọn. 4 Èyí ̀gbọ́n ń jẹ́ Ohola, àbúrò rẹ̀ ń jẹ́ Oholiba. Tèmi ni wọ́n, wọ́n àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin. Ohola ni Samaria, Oholiba ni Jerusalẹmu.

5 "Ohola ń ṣe panṣágà nígbà ó jẹ́ tèmi; Ó ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, àwọn jagunjagun ará Asiria. 6 Aṣọ aláró ni a fi wọ̀ wọ́n, àwọn gómìnà àti àwọn balógun, gbogbo wọn jẹ́ ̀dọ́mọkùnrin arẹwà àwọn ń gun ẹṣin. 7 O fi ara rẹ̀ fún gbajúmọ̀ ọkùnrin Asiria gẹ́gẹ́ panṣágà obìnrin, o fi òrìṣà gbogbo àwọn ó ìfẹ́kúfẹ̀́ i sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́, 8 fi ìwà panṣágà ó ti bẹ̀rẹ̀, ni Ejibiti sílẹ̀, ìgbà èwe rẹ̀ àwọn ọkùnrin n a sùn, wọn fi ọwọ́ pa àyà èwe rẹ̀ lára wọn ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ i.

9 "Nítorí náà mo fi i sílẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, ará Asiria, ó ìfẹ́kúfẹ̀́ i. 10 Wọ́n bọ́ ìhòhò, wọ́n gba àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ̀ wọn pa wọn pẹ̀idà. Ó di ẹni ìfisọ̀rọ̀ sọ láàrín àwọn obìnrin wọ́n fi ìyà jẹ ́.

11 "Àbúrò rẹ̀ Oholiba èyí, síbẹ̀ nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ àti panṣágà rẹ̀, Ó ba ara rẹ jẹ́ ju ̀gbọ́n rẹ̀ lọ. 12 Òun náà ìfẹ́kúfẹ̀́ ará Asiria àwọn gómìnà àti àwọn balógun, jagunjagun nínú aṣọ ogun, àwọn ń gun ẹṣin, gbogbo àwọn ̀dọ́mọkùnrin arẹwà. 13 Mo i òun náà ba ara rẹ̀ jẹ́; àwọn méjèèjì rìn ojú ̀kan náà.

14 "Ṣùgbọ́n ó tẹ̀síwájú nínú ṣíṣe panṣágà. O ri àwòrán àwọn ọkùnrin lára ògiri, àwòrán àwọn ara Kaldea àwòrán pupa, 15 pẹ̀ìgbànú ni ìdí wọn àti àwọn ìgbàrí ni orí wọn; gbogbo wọn dàbí olórí kẹ̀kẹ́ ogun Babeli ọmọ ìlú Kaldea. 16 kété ó wọn, ó ìfẹ́kúfẹ̀́ wọn, ó rán oníṣẹ́ wọn ni Kaldea. 17 Àwọn ará Babeli sọ́dọ̀ rẹ̀, lórí ibùsùn ìfẹ́, nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ wọn, wọ́n á jẹ́. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n á jẹ́ tán, ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn ìtìjú. 18 Nígbà ó tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ panṣágà rẹ̀ gbangba wọ́n u ìhòhò, mo padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ìtìjú, gẹ́gẹ́ mo ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ ̀gbọ́n rẹ̀. 19 Síbẹ̀síbẹ̀ ó ń pọ̀ i nínú ìdàpọ̀ rẹ̀ ó ti ń rántí ìgbà èwe rẹ̀ ó jẹ́ panṣágà Ejibiti. 20 Nítorí ó fẹ́ olùfẹ́ àwọn olùfẹ́ wọn àfẹ́, àwọn nǹkan ọkùnrin wọn dàbí ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àwọn ẹni ìtújáde ara wọn dàbí ti àwọn ẹṣin. 21 Báyìí ni ìwọ pe ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ ìgbà èwe rẹ ìrántí, ti rírin orí ọmú rẹ láti ọwọ́ àwọn ará Ejibiti, fún ọmú ìgbà èwe rẹ.

22 "Nítorí náà, Oholiba, báyìí Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò gbé olólùfẹ́ rẹ dìde , àwọn o kẹ́yìn si ìtìjú, èmi yóò wọn dojúkọ ́ gbogbo ̀23 àwọn ará Babeli àti gbogbo ara Kaldea àwọn ọkùnrin Pekodi àti Ṣoa àti Koa àti gbogbo ará Asiria pẹ̀wọn, àwọn ̀dọ́mọkùnrin arẹwà, gbogbo àwọn gómìnà àti balógun, olórí oníkẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn onípò gíga, gbogbo àwọn ń gun ẹṣin. 24 Wọn yóò wa dojúkọ pẹ̀ohun ìjà, kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀kẹ̀kẹ́ ẹrù àti pẹ̀ìwọ́jọpọ̀ ènìyàn; wọn yóò ìdúró wọn lòdì gbogbo ̀pẹ̀asà ńlá àti kékeré pẹ̀àṣíborí. Èmi yóò padà wọn fun ìjìyà, wọn yóò fi ìyà jẹ gẹ́gẹ́ wọn . 25 Èmi yóò dojú ìbínú owú mi kọ ́, wọn yóò fìyà jẹ ́ ìrunú. Wọ́n yóò àwọn imú àti àwọn etí yín kúrò, àwọn ó nínú yín yóò ti ipá idà ṣubú. Wọn yóò àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọkùnrin yín lọ, àwọn o nínú yín ni iná yóò jórun. 26 Wọn yóò àwọn aṣọ àti àwọn ohun ̀ṣọ́ iyebíye yín. 27 Èmi yóò fi òpin ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ àti iṣẹ́ panṣágà bẹ̀rẹ̀ ni Ejibiti. ̀yin wo àwọn nǹkan wọ̀nyí pẹ̀ìpòùngbẹ, bẹ́̀ ni rántí Ejibiti mọ.

28 "Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò fi ọwọ́ àwọn ó kórìíra, lọ́wọ́ àwọn ẹni ọkàn rẹ ti ṣí kúrò. 29 Wọn yóò fìyà jẹ ́ pẹ̀ìkórìíra, wọn yóò gbogbo ohun o ṣiṣẹ́ fún lọ. Wọn yóò fi ́ sílẹ̀ ìhòhò goloto, ìtìjú iṣẹ́ panṣágà rẹ ni yóò farahàn. Ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀ àti panṣágà rẹ. 30 Èmi yóò ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí , nítorí ìwọ ti àwọn kèfèrí ṣe àgbèrè lọ, o fi àwọn òrìṣà wọn ba ara rẹ̀ jẹ́. 31 Ìwọ ti rin ̀ti ̀gbọ́n rẹ rìn, Èmi yóò fi ago rẹ̀ lọ́wọ́.

32 "Èyí yìí ohun ti Olúwa Olódùmarè :

"Ìwọ yóò mu nínú ago ̀gbọ́n rẹ,

ago ó tóbi ó jinnú:

yóò ìfiṣẹ̀sín àti ìfiṣe ẹlẹ́,

nítorí ago náà gba nǹkan púpọ̀.

33 Ìwọ yóò mu àmupara àti ìbànújẹ́,

ago ìparun àti ìsọdahoro

ago ̀gbọ́n rẹ Samaria.

34 Ìwọ yóò un ni àmugbẹ;

ìwọ yóò fọ wẹ́wẹ́

ìwọ yóò fa ọmú rẹ̀ ya.

Èmi ti sọ̀rọ̀ ni Olúwa Olódùmarè .

35 "Nítorí náà báyìí Olúwa Olódùmarè : Níwọ́n ìwọ ti gbàgbé mi, ìwọ ti fi mi ̀yìn rẹ, ìwọ gbọdọ̀ gba àbájáde ìfẹ́kúfẹ̀́ àti panṣágà rẹ."

36 Olúwa sọ fún mi : "Ọmọ ènìyàn, ń jẹ́ ìwọ yóò ṣe ìdájọ́ Ohola àti Oholiba? Nítorí náà dojúkọ wọn nípa ìkórìíra wọn ń ṣe, 37 nítorí wọn ti ̀ṣẹ̀ panṣágà ̀jẹ̀ ọwọ́ wọn. Wọn ̀ṣẹ̀ panṣágà pẹ̀àwọn òrìṣà wọn; kódà wọ́n fi àwọn ọmọ wọn wọn fún ni ṣe ìrúbọ, gẹ́gẹ́ oúnjẹ fún wọn. 38 Bákan náà ni wọ́n ti ṣe èyí náà mi. àkókò kan náà wọn ba ibi mímọ́ mi jẹ́, wọ́n lo ọjọ́ ìsinmi mi àìmọ́. 39 ọjọ́ náà gan an wọ́n fi àwọn ọmọ wọn ẹbọ àwọn òrìṣà, wọn wọ ibi mímọ́ mi lọ wọn ó ìlòkulò. Ìyẹn wọn ṣe ilé mi.

40 "Wọn tilẹ̀ rán oníṣẹ́ àwọn ènìyàn wọ́n láti ̀jíjìn, nígbà wọ́n , ìwọ wẹ ara rẹ fún wọn, ìwọ kún ojú rẹ, ìwọ fi ̀ṣọ́ iyebíye sára. 41 Ìwọ jókòó lórí ibùsùn ti o lẹ́, pẹ̀tábìlì a tẹ́ iwájú rẹ lórí, èyí o gbé tùràrí àti òróró ó jẹ́ tèmi .

42 "Ariwo ìjọ ènìyàn bìkítà àyíká rẹ̀; a àwọn ara Sabeani láti aginjù pẹ̀àwọn ọkùnrin láti ara àwọn ̀pọ̀ ènìyàn aláìníláárí, wọ́n àwọn ̀gbà ọrùn ọwọ́ àwọn ọwọ́ obìnrin náà àti ̀gbọ́n rẹ̀, adé dáradára orí wọn. 43 Lẹ́yìn náà mo sọ̀rọ̀ nípa èyí ó lo ara rẹ̀ nípa panṣágà ṣíṣe, Nísinsin yìí jẹ wọn lo o panṣágà, nítorí gbogbo ohun ó jẹ́ nìyẹn.44 Wọn ba sùn ọkùnrin ti panṣágà sùn, bẹ́̀ ni wọ́n ṣe sùn pẹ̀obìnrin onífẹ̀kúfẹ̀́, Ohola àti Oholiba. 45 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin olódodo yóò pàṣẹ wọ́n fi ìyà jẹ àwọn obìnrin ó ̀ṣẹ̀ àgbèrè ó ta ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí panṣágà ni wọ́n ̀jẹ̀ ọwọ́ wọn.

46 "Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè : àgbájọ àwọn ènìyànkénìyàn sọ́dọ̀ wọn ki ó fi wọn ọwọ́ ìpayà àti ìkógun. 47 Àwọn ènìyànkénìyàn náà yóò sọ wọ́n ni òkúta, yóò wọn lulẹ̀ pẹ̀idà wọn; wọn ó pa àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, wọ́n ó àwọn ilé wọn kanlẹ̀."

48 "Èmi yóò fi òpin ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ ni ilẹ̀ náà, gbogbo àwọn obìnrin le gba ìkìlọ̀ wọn ó ma ṣe fi ara . 49 Ìwọ yóò jìyà fún ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ, ìwọ yóò gba àbájáde àwọn ̀ṣẹ̀ panṣágà o . Nígbà náà ìwọ yóò mọ̀ èmi ni Olúwa Olódùmarè."

Veja também