Publicidade

Isaías 49

Ìránṣẹ́ Olúwa Náà

1 Tẹ́mi, ̀yin erékùṣù:

gbọ́ èyí, ̀yin orílẹ̀-èdè jíjìnnà réré:

a mi Olúwa ti ;

láti ìgbà bíbí mi ni ó ti orúkọ mi.

2 Ó ṣe ẹnu mi idà a pọ́n,

abẹ́ òjìji ọwọ́ rẹ̀ ni ó ti pa mọ́:

ó ṣe ọfà a ti dán,

ó fi pamọ́ sínú àpò rẹ̀.

3 Ó sọ fún mi , "Ìránṣẹ́ mi ni ìwọ í ṣe,

Israẹli nínú ẹni n ó ti fi ògo mi hàn."

4 Ṣùgbọ́n èmi sọ , "Mo ti ṣe wàhálà lórí asán;

mo ti lo gbogbo ipá mi lórí asán àti ìmúlẹ̀mófo.

Síbẹ̀síbẹ̀ ohun ó tọ́ mi ṣì lọ́wọ́ Olúwa,

èrè mi ń bẹ pẹ̀Ọlọ́run mi."

5 Nísinsin yìí Olúwa

ẹni ó mọ̀ láti inú láti jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀

láti Jakọbu padà tọ̀

àti láti Israẹli jọ sọ́dọ̀ ara rẹ̀,

nítorí a bọ̀wọ̀ fún mi ojú Olúwa

Ọlọ́run mi ti jẹ́ agbára mi,

6 Òun :

"Ó jẹ́ ohun kékeré fún láti jẹ́ ìránṣẹ́ mi

láti ̀Jakọbu padà bọ̀ sípò

àti láti àwọn ti Israẹli mo ti pamọ́.

Èmi yóò fi ́ ṣe ìmọ́lẹ̀ fún àwọn kèfèrí,

ìwọ ó ìgbàlà mi

òpin ilẹ̀ ayé."

7 Ohun Olúwa nìyìí,

Olùdáǹdè àti Ẹni Mímọ́ Israẹli

ẹni náà a gàn a kórìíra

lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,

ìránṣẹ́ àwọn aláṣẹ:

"Àwọn ọba yóò wọn yóò dìde sókè,

àwọn ọmọ ọba yóò i wọn yóò wólẹ̀,

nítorí Olúwa ẹni í ṣe olóòtítọ́,

Ẹni Mímọ́ Israẹli ó ti yàn ́."

Ìmúpadàbọ̀sípò Israẹli

8 Ohun Olúwa nìyìí:

"àkókò ojúrere mi, èmi yóò lóhùn,

àti ọjọ́ ìgbàlà, èmi yóò ràn ́ lọ́wọ́;

Èmi yóò pa ́ mọ́, n ó ṣe ́

láti jẹ́ májẹ̀fún àwọn ènìyàn,

láti ilẹ̀ padà bọ̀ sípò

àti láti ṣe àtúnpín ogún rẹ̀ ó ti dahoro,

9 láti sọ fún àwọn ìgbèkùn , jáde ,

àti fún àwọn ó nínú òkùnkùn , gba òmìnira!

"Wọn yóò máa jẹ ̀̀

àti koríko tútù lórí òkè aláìléwéko.

10 Ebi yóò pa wọ́n bẹ́̀ ni òǹgbẹ yóò gbẹ wọ́n,

tàbí ooru inú aṣálẹ̀ tàbí oòrùn ó pa wọ́n.

Ẹni ó ṣàánú fún wọn ni yóò máa tọ́ wọn,

yóò wọn lọ ibi orísun omi.

11 Èmi yóò sọ gbogbo àwọn òkè ńlá mi di ojú ̀

àti gbogbo òpópónà mi ni a ó gbé sókè.

12 Kíyèsi i, wọn yóò láti ̀jíjìn

àwọn díẹ̀ láti àríwá àti àwọn díẹ̀ láti ìwọ̀-oòrùn,

àwọn díẹ̀ láti ẹkùn Siene."

13 fún ayọ̀, ẹyin ̀run;

yọ̀, ìwọ ilẹ̀ ayé;

sórin, ̀yin òkè ńlá!

Nítorí Olúwa tu àwọn ènìyàn rẹ̀ nínú

yóò ṣàánú fún àwọn ẹni

a ń pọ́n lójú.

14 Ṣùgbọ́n Sioni sọ , "Olúwa ti kọ̀ sílẹ̀,

Olúwa ti gbàgbé è mi."

15 "Ǹjẹ́ abiyamọ ha le gbàgbé ọmọ ọmú rẹ̀

ó ṣàánú fún ọmọ rẹ̀ ó ti ?

ó tilẹ̀ jẹ́ òun le gbàgbé,

Èmi yóò gbàgbé rẹ!

16 Kíyèsi i, mo ti kọ ́ àtẹ́lẹwọ́ mi

ògiri rẹ níwájú mi nígbà gbogbo.

17 Àwọn ọmọ rẹ ti kánjú padà,

àti àwọn ó sọ ́ dahoro ti padà lẹ́yìn rẹ.

18 Gbójú rẹ sókè o yíká;

gbogbo àwọn ọmọkùnrin rẹ kórajọ

wọ́n sọ́dọ̀ rẹ.

Níwọ́n ìgbà mo láààyè," ni Olúwa ,

"Ìwọ yóò wọ gbogbo wọ́n gẹ́gẹ́ ohun ̀ṣọ́;

ìwọ yóò wọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ ìyàwó.

19 "ó tilẹ̀ jẹ́ a run ́, a sọ ́ di ahoro

gbogbo ilẹ̀ rẹ di ìparun,

ìsinsin yìí, ìwọ yóò kéré fún àwọn ènìyàn rẹ,

bẹ́̀ ni àwọn ó jẹ ́ run ni yóò

láti ̀jíjìn réré.

20 Àwọn ọmọ a àkókò ̀fọ̀ rẹ

yóò sọ etígbọ̀́ rẹ,

Ibi yìí ti kéré fún wa;

fún wa láyè i a ó máa gbé.

21 Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ ọkàn rẹ ,

Ta àwọn yìí fún mi?

Mo ti ṣọ̀fọ̀ mo yàgàn;

a sọ mi di àtìpó a kọ̀ sílẹ̀.

Ta wo àwọn yìí dàgbà?

A fi èmi nìkan sílẹ̀,

ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí níbo ni wọ́n ti ?’ "

22 Ohun Olúwa Olódùmarè nìyìí,

"Kíyèsi i, Èmi yóò àwọn aláìkọlà,

Èmi yóò gbé àsíá mi sókè ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn;

wọn yóò àwọn ọmọkùnrin yín apá wọn

wọn yóò gbé àwọn ̀dọ́mọbìnrin

èjìká wọn.

23 Àwọn ọba ni yóò jẹ́ alágbàtọ́ baba fún ,

àwọn ayaba wọn ni yóò jẹ́ ìyá-alágbàtọ́.

Wọn yóò foríbalẹ̀ iwájú rẹ̀ pẹ̀ojú wọn dídàbolẹ̀;

wọn yóò máa erùpẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ.

Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa;

gbogbo àwọn wọ́n ìrètí nínú mi

ni a yóò jákulẹ̀."

24 Ǹjẹ́ a le gba ìkógun lọ́wọ́ jagunjagun,

tàbí á gba ìgbèkùn lọ́wọ́ akíkanjú?

25 Ṣùgbọ́n ohun Olúwa nìyìí:

"Bẹ́̀ ni, a ó gba àwọn ìgbèkùn lọ́wọ́ àwọn jagunjagun,

àti ìkógun lọ́wọ́ àwọn akíkanjú;

ẹni ó ni èmi ó ,

àti àwọn ọmọ rẹ ni èmi ó gbàlà.

26 Èmi yóò àwọn aninilára rẹ̀ jẹ ẹran-ara wọn;

wọn yóò mu ̀jẹ̀ ara wọn ẹni mu wáìnì.

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn yóò mọ̀

, Èmi, Olúwa, èmi ni Olùgbàlà rẹ,

Olùdáǹdè rẹ, Alágbára kan ṣoṣo ti Jakọbu."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-