Pular para o conteúdo
Publicidade

Ezequiel 16

Òwe nípa àìṣòdodo Jerusalẹmu

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, Jerusalẹmu mọ gbogbo ìwà ìríra rẹ̀. 3 16.3: El 16.45.Sọ , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè Jerusalẹmu, ìran rẹ àti ilẹ̀ ìbí rẹ ilẹ̀ Kenaani; ará Amori ni baba rẹ̀, ìyá rẹ̀ jẹ́ ará Hiti. 4 ọjọ́ a , a okùn ìwọ́ rẹ, bẹ́̀ ni a fi omi wẹ̀ ́ láti o mọ́, a fi iyọ̀ pa ́ lára rárá, bẹ́̀ ni a fi aṣọ . 5 ẹni ṣàánú tàbí kẹ́dùn rẹ bi à ti ṣe nǹkan kan nínú ìwọ̀nyí fún , ṣùgbọ́n lọ́jọ́ ìbí rẹ, ìta la ́ torí wọ́n kórìíra rẹ.

6 " Nígbà mo kọjá mo ń jàgùdù nínú ̀jẹ̀ rẹ, mo sọ fún , "!" Nítòótọ́, nígbà ìwọ nínú ̀jẹ̀ rẹ , "." 7 Mo dàgbà ohun ̀gbìn inú oko. O ga sókè, o dàgbà, o di arẹwà jùlọ, ọmú rẹ yọ, irun rẹ gùn, ìwọ o ìhòhò láìfi nǹkan kan bora.

8 " Nígbà mo tún kọjá, mo , mo i àsìkò àti nífẹ̀́ rẹ ti , mo fi ìṣẹ́aṣọ mi bo ìhòhò rẹ. Mo búra fún , èmi májẹ̀ìwọ di tèmi, ni Olúwa Olódùmarè .

9 " Nígbà náà ni mo fi omi wẹ ̀jẹ̀ kúrò ara rẹ, mo fi ìpara pa ́ lára. 10 Mo fi aṣọ oníṣẹ́-ọnà lára láti wọ̀ ́, mo wọ bàtà aláwọ fún . Mo fi aṣọ funfun gbòò àti aṣọ olówó iyebíye ṣe ́ lọ́ṣọ̀́. 11 Mo fi ohun ̀ṣọ́ ṣe ́ lọ́ṣọ̀́, mo fi ̀gbà ọwọ́ ọwọ́, mo fi ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn ọrùn, 12 mo tún fi òrùka imú, mo fi yẹtí etí, mo fi adé rẹwà orí. 13 Báyìí ni mo ṣe ́ lọ́ṣọ̀́ pẹ̀wúrà àti fàdákà; aṣọ rẹ jẹ́ funfun gbòò, aṣọ olówó iyebíye àti aṣọ a ṣiṣẹ́ ọnà . Ìyẹ̀fun kíkúnná, oyin àti òróró ni oúnjẹ rẹ. Ó di arẹwà títí ó fi ipò ayaba. 14 Òkìkí rẹ kàn káàkiri orílẹ̀-èdè nítorí ẹwà rẹ, nítorí dídán mo fi ṣe ẹwà rẹ àṣepé, ni Olúwa Olódùmarè .

15 " Ṣùgbọ́n, ìwọ gbẹ́kẹ̀ẹwà rẹ, ìwọ di alágbèrè nítorí òkìkí rẹ. Ìwọ fọ́n ojúrere rẹ káàkiri orí ẹni yówù ń kọjá lọ, ẹwà rẹ di tìrẹ. 16 Ìwọ lára àwọn aṣọ rẹ, láti rán aṣọ aláràbarà fún ibi gíga òrìṣà ìwọ ti ń ṣe àgbèrè. Èyí yẹ ó bẹ́̀, tàbí tilẹ̀ ṣẹlẹ̀ rárá. 17 Ìwọ tún àwọn ohun ̀ṣọ́ dáradára mo fi wúrà àti fàdákà ṣe fún láti fi ère ọkùnrin ó ń ṣe àgbèrè papọ̀. 18 Ìwọ wọ aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́ rẹ fún wọn, o tún gbé òróró àti tùràrí mi sílẹ̀ níwájú wọn. 19 Ìwọ tún gbé oúnjẹ mo fún ìyẹ̀fun dáradára, òróró àti oyinfún wọn gẹ́gẹ́ ẹbọ sísun olóòórùn dídùn; ohun ṣẹlẹ̀ nìyìí, ni Olúwa Olódùmarè .

20 " Àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin o fún mi lo ti fi ẹbọ oúnjẹ fún àwọn òrìṣà. Ṣé ìwà àgbèrè rẹ ha ? 21 ìwọ ti pa àwọn ọmọ , ìwọ wọ́n fún ère gẹ́gẹ́ ẹbọ sísun. 22 Nínú gbogbo iṣẹ́ ìríra àti ìwà àgbèrè rẹ, ìwọ rántí ìgbà èwe rẹ, nígbà ìwọ ìhòhò, ń jàgùdù nínú ̀jẹ̀.’

23 "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Ègbé! Ègbé ni fún . Lẹ́yìn gbogbo ìwà búburú rẹ, 24 ìwọ kọ́amọ̀ fún ara rẹ, ìwọ kọ́ ojúbọ gíga gbogbo òpin ojú pópó. 25 gbogbo ìkóríta ni ìwọ lọ kọ ojúbọ gíga , ìwọ sọ ẹwà rẹ di ìkórìíra, ìwọ sọ àgbèrè rẹ di púpọ̀ nípa fífi ara rẹ sílẹ̀ fún gbogbo ẹni ń kọjá lọ. 26 Ìwọ ti ṣe àgbèrè pẹ̀ará Ejibiti í ṣe aládùúgbò rẹ láti mi bínú ìwọ ti sọ àgbèrè rẹ di púpọ̀. 27 Nítorí náà ni mo fi na ọwọ́ mi lórí, mo ti bu oúnjẹ rẹ̀ ; èmi yóò ìfẹ́ àwọn to kórìíra rẹ ṣẹ́ lórí, àwọn ọmọbìnrin Filistini ti ìwàkiwà rẹ lójú. 28 Nítorí àìnítẹ́lọ́rùn rẹ, ìwọ ti ṣe àgbèrè pẹ̀ara Asiria; ìwọ ti wọn ṣe àgbèrè, síbẹ̀síbẹ̀, tẹ́ lọ́rùn. 29 Ìwọ si ti sọ àgbèrè rẹ di púpọ̀ láti ilẹ̀ Kenaani ilẹ̀ Kaldea; síbẹ̀ èyí tẹ́ lọ́rùn níhìn-ín yìí.

30 "Olúwa Olódùmarè , Báwo ni ọkàn rẹ ṣe jẹ aláìlera o ń ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí, iṣẹ́ àwọn agídí alágbèrè! 31 Ni ti ìwọ kọ́ ilé gíga rẹ ni gbogbo ìkóríta, ìwọ ṣe gbogbo ibi gíga rẹ ni gbogbo ìta, ìwọ wa dàbí panṣágà obìnrin, ti ìwọ gan ̀.

32 " Ìwọ alágbèrè aya! Ìwọ fẹ́ràn ọkùnrin àjèjì ju ọkọ rẹ lọ! 33 Àwọn ọkùnrin máa ń sanwó fún àwọn panṣágà ni ṣùgbọ́n ìwọ lo tún ń sanwó fun wọn, ó tún ń fún àwọn olólùfẹ́ rẹ lẹ́bùn àti owó ̀yìn wọn à le máa láti gbogbo agbègbè fún àgbèrè ṣíṣe. 34 Nínú àgbèrè rẹ ìwọ yàtọ̀ àwọn alágbèrè obìnrin yòókù; nínú àgbèrè rẹ ẹnìkan tẹ̀láti ṣe àgbèrè; àti ti ìwọ ń tọrẹ a tọrẹ fún , nítorí náà ìwọ yàtọ̀.

35 " Nítorí náà, ìwọ alágbèrè, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa! 36 Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , "Nítorí ìwọ ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ jáde, ìwọ fi ìhòhò rẹ hàn, nípa ṣíṣe àgbèrè pẹ̀àwọn olólùfẹ́ rẹ, àti nítorí gbogbo òrìṣà ìríra o fi ̀jẹ̀ àwọn ọmọ rẹ ṣe ìrúbọ fún, 37 nítorí náà, Èmi yóò ṣa gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ jọ, àwọn ẹni ti ìwọ ti jayé àti gbogbo àwọn ìwọ ti fẹ́ àti àwọn ìwọ kórìíra. Èmi yóò sa gbogbo wọn káàkiri jọ, láti wọn lòdì , èmi yóò aṣọ rẹ, níwájú wọn, wọn yóò ìhòhò rẹ. 38 Èmi yóò lẹ́jọ́, gẹ́gẹ́ a ti obìnrin ba ìgbéyàwó jẹ́, wọn ta ̀jẹ̀ sílẹ̀; Èmi yóò ̀jẹ̀ ìbínú àti owú mi sórí rẹ. 39 Nígbà náà ni èmi yóò àwọn olólùfẹ́ rẹ lọ́wọ́, wọn yóò gbogbo òkìtì rẹ pẹ̀àwọn ojúbọ rẹ palẹ̀. Wọn yóò aṣọ kúrò lára rẹ̀, gbogbo ̀ṣọ́ rẹ ni wọn yóò gbà, wọn yóò fi sílẹ̀ ìhòhò àti àìwọṣọ. 40 Wọn yóò pe àjọ ènìyàn jọ lórí, àwọn yóò sọ ́ òkúta, tiwọn yóò fi idà wọn wẹ́wẹ́. 41 Wọn yóò jo gbogbo ilé rẹ palẹ̀ wọn yóò fi ìyà jẹ ́ ojú àwọn obìnrin. Èmi yóò fi òpin àgbèrè ṣíṣe rẹ. Ìwọ san owó fún àwọn olólùfẹ́ rẹ mọ́. 42 Nígbà náà ni ìbínú mi o yóò rọ̀, owú ìbínú mi yóò kúrò lọ́dọ̀ rẹ; inú mi yóò rọ̀, èmi bínú mọ́."

43 " Nítorí ìwọ rántí ọjọ́ èwe rẹ ṣùgbọ́n ìwọ ń mi fín pẹ̀gbogbo nǹkan wọ̀nyí, ó dájú , Èmi yóò gbogbo ohun ìwọ ti ṣe wa orí rẹ, ni Olúwa Olódùmarè , ìwọ yóò ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ yìí ni orí gbogbo ohun ìríra rẹ mọ́?

44 " Gbogbo àwọn to ń pòwe, ni yóò máa pòwe yìí mọ́ : "ìyá ṣe , bẹ́̀ ni ọmọ rẹ̀ obìnrin." 45 Ìwọ ni ọmọ ìyá rẹ ti ó kọ ọkọ rẹ̀, àti àwọn ọmọ rẹ̀; ìwọ ni arábìnrin àwọn arábìnrin rẹ ó kọ àwọn ọkọ wọn àti àwọn ọmọ wọn: ara Hiti ni ìyá rẹ, ara Amori ni baba rẹ. 46 ̀gbọ́n rẹ obìnrin ni Samaria, òun àti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ n gbé ni apá àríwá rẹ, àti àbúrò rẹ obìnrin ń gbé ọwọ́ òsì rẹ̀, àti àbúrò rẹ obìnrin ti ń gbé ọwọ́ ̀tún rẹ ni Sodomu àti àwọn ọmọ rẹ obìnrin. 47 í sẹ ìwọ rìn ni ̀wọn nìkan, tàbí ṣe àfiwé ìwà ìríra wọn ṣùgbọ́n àárín àkókò kúkúrú díẹ̀, ìwọ bàjẹ́ wọ́n lọ 48 Olúwa Olódùmarè , "mo ṣe láààyè, Sodomu í ṣe ̀gbọ́n rẹ obìnrin àti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ ṣe to ohun ìwọ àti ọmọbìnrin rẹ ṣe."

49 " ó, ̀ṣẹ̀ Sodomu ̀gbọ́n rẹ̀ obìnrin ṣẹ̀ nìyìí. Òun àti àwọn ọmọbìnrin rẹ gbéraga, wọ́n jẹ́ alájẹjù àti aláìbìkítà; wọn ran tálákà àti aláìní lọ́wọ́. 50 Nítorí náà, mo mu wọn kúrò níwájú mi lójú mi gẹ́gẹ́ bi ìwọ ti ó, nítorí ìgbéraga àti àwọn ohun ìríra wọ́n ṣe. 51 Samaria ṣe ìdajì ̀ṣẹ̀ rẹ. Ìwọ ṣe àwọn ohun ìríra ju tirẹ̀ lọ, ìwọ jẹ àwọn arábìnrin rẹ dàbí olódodo pẹ̀gbogbo ìwọ̀nyí ìwọ ti ṣe. 52 Gba ìtìjú rẹ, nítorí ìwọ ti jẹ́ arábìnrin rẹ gba ìdáláre. Nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ ti burú ju wọn lọ, wọn dàbí olódodo ju ìwọ lọ. Nítorí náà ìtìjú rẹ, o gba ̀gàn rẹ pẹ̀nítorí ìwọ ti jẹ́ àwọn arábìnrin rẹ dàbí olódodo.

53 " Bi o tilẹ̀ jẹ pe èmi yóò ìgbèkùn wọn padà, ìgbèkùn Sodomu àti àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin, pẹ̀Samaria àti àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin, nígbà náà ni èmi yóò tún ìgbèkùn àwọn òǹdè rẹ láàrín wọn, 54 ó à le ìtìjú rẹ, àti ̀gàn gbogbo ohun ìwọ ṣe láti wọ́n nínú. 55 Nígbà àwọn arábìnrin rẹ, Sodomu àti àwọn ọmọbìnrin rẹ; Samaria àti àwọn ọmọbìnrin rẹ ba padà si ipò wọn tẹ́lẹ̀, ìgbà náà ni ìwọ náà yóò padà ipò àtijọ́ rẹ. 56 Ìwọ ko tilẹ̀ dárúkọ arábìnrin rẹ Sodomu ni ọjọ́ ìgbéraga rẹ, 57 di àṣírí ìwà búburú rẹ síta, báyìí ìwọ di ẹni ̀gàn lọ́dọ̀ àwọn ọmọbìnrin Edomu, Siria àti gbogbo agbègbè rẹ, àti lọ́dọ̀ àwọn ọmọbìnrin Filistini àti lọ́dọ̀ àwọn , tiwọn si ń kẹ́gàn rẹ. 58 Èmi yóò gba ̀san ìwà ìfẹ́kúfẹ̀́ àti àwọn iṣẹ́ ìríra rẹ Olúwa .

59 "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò hùwà gẹ́gẹ́ bi ó ṣe tọ́ , nítorí ó ti kẹ́gàn ̀jẹ́ nípa dídà májẹ̀. 60 Síbẹ̀ èmi yóò rántí májẹ̀mo ṣe nígbà èwe rẹ, èmi yóò májẹ̀láéláé. 61 Nígbà náà ni ìwọ yóò rántí àwọn ̀rẹ ojú yóò ́ nígbà mo gba àwọn ̀gbọ́n àti àbúrò rẹ obìnrin padà. Fún gẹ́gẹ́ ọmọbìnrin, ṣùgbọ́n í ṣe lórí májẹ̀mo . 62 Èmi yóò gbé májẹ̀mi kalẹ̀ pẹ̀rẹ, ìwọ yóò mọ èmi ni Olúwa. 63 Nígbà mo ti ṣe ètùtù fún gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ tan, Èmi yóò rántí, ojú yóò ́, ìwọ le ya ẹnu rẹ mọ́ nítorí ìtìjú rẹ, ni Olúwa Olódùmarè .’ "

Veja também