Publicidade

Ezequiel 3

1 Síwájú i, ó sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, jẹ ohun ó níwájú rẹ, jẹ ìwé kíká yìí; o lọ fi ilé Israẹli sọ̀rọ̀." 2 Mo ya ẹnu mi, ó mi jẹ ìwé kíká náà.

3 Ó tún sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, jẹ ìwé kíká mo fún yìí, fi bọ́ inú àti ikùn rẹ." Nígbà náà ni mo jẹ ́, dídùn rẹ̀ dàbí oyin ẹnu mi.

4 Ó tún sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, lọ ni ìsinsin yìí mi sọ ̀rọ̀ mi fún ilé Israẹli. 5 A rán àwọn ń sọ èdè àjèjì tàbí èdè wọn ṣòro láti gbọ́, ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè Israẹli ni mo rán 6 í ṣe ̀pọ̀ ènìyàn ń sọ àjèjì èdè tàbí èdè wọn ṣòro láti gbọ́, àwọn ̀rọ̀ wọn le fún láti gbọ́ . Dájúdájú mo rán wọn, wọn ìbá fetísílẹ̀ . 7 Ṣùgbọ́n ilé Israẹli fẹ́ gbọ́ tìrẹ nítorí wọn fẹ́ láti gbọ́ tèmi, torí aláìgbọ́ràn àti ọlọ́kàn líle ni gbogbo ilé Israẹli. 8 Ṣùgbọ́n i tiwọn lèmi náà yóò ṣe jẹ́ ojú àti ọkàn rẹ le. 9 Èmi yóò ṣe iwájú orí rẹ òkúta le jùlọ, ànító le ju òkúta-ìbọn lọ. ṣe bẹ̀wọn tàbí jẹ́ wọn ó dáyà . ó tilẹ̀ jẹ́ ìdílé ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n."

10 Ó sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ mo ń sọ, o gba gbogbo ̀rọ̀ yìí ọkàn rẹ. 11 Lọ nísinsin yìí ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ ìgbèkùn. Sọ fún wọn báyìí ni Olúwa Olódùmarè yálà wọ́n gbọ́ tàbí wọn gbọ́."

12 Nígbà náà ni ̀gbé mi sókè, mo gbọ́ ohùn ìró ńlá lẹ́yìn mi sọ , a gbé ògo Olúwa ga láti ibùgbé rẹ̀ ! 13 Bẹ́̀ ni mo tún gbọ́ ariwo ìyẹ́ apá àti kẹ̀kẹ́ àwọn ̀alààyè náà pẹ̀ariwo dàbí àrá ńlá. 14 ̀náà gbé mi sókè, ó mi lọ, mo lọ pẹ̀ọkàn kíkorò àti ìbínú nínú ̀mi, pẹ̀ọwọ́ líle Olúwa ni ara mi. 15 Nígbà náà ni mo lọ etí odò Kebari níbi àwọn ìgbèkùn ń gbé ni Teli-Abibu. Níbẹ̀ níbi wọ́n ń gbé, mo jókòó láàrín wọn pẹ̀ìyanu, fún ọjọ́ méje.

Ìkìlọ̀ Israẹli

16 3.16-21: El 33.1-9. Lẹ́yìn ọjọ́ méje, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , 17 "Ọmọ ènìyàn, mo ti fi ́ ṣe olùṣọ́ fún ilé Israẹli; nítorí náà gbọ́ ̀rọ̀ mo ń sọ, fún wọn ìkìlọ̀ láti ̀dọ̀ mi. 18 mo sọ fún ènìyàn búburú , dájúdájú, Ìwọ yóò ,ìwọ kìlọ̀ fún ènìyàn búburú yìí láti dáwọ́ ìwà ibi rẹ̀ dúró, o gba ̀rẹ̀ , ènìyàn búburú náà yóò nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ọwọ́ rẹ ni èmi yóò ti béèrè ̀jẹ̀ rẹ̀. 19 Ṣùgbọ́n o kìlọ̀ fún ènìyàn búburú, ó kọ̀ fi ìwà búburú rẹ̀ sílẹ̀, yóò sínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀; ṣùgbọ́n ọrùn tìrẹ ti mọ́.

20 "Bákan náà, olódodo kan yípadà, bẹ̀rẹ̀ í ṣe àìṣòdodo, mo fi ohun ìkọ̀sẹ̀ ̀rẹ̀, yóò sínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀. Nítorí ìwọ kọ̀ láti kìlọ̀ fún un, yóò sínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, a ó gbàgbé gbogbo ìwà rere ti tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n ọwọ́ rẹ̀ ni èmi yóò ti béèrè ̀jẹ̀ rẹ̀. 21 Ṣùgbọ́n o kìlọ̀ fún olódodo dáwọ́ ìwà ̀ṣẹ̀ rẹ̀ dúró, dájúdájú òun yóò nítorí ó ti gba ìkìlọ̀, ọrùn tìrẹ mọ́."

22 Ọwọ́ Olúwa lára mi níbẹ̀, ó fún mi , "Dìde, lọ ibi ó tẹ́, èmi yóò sọ̀rọ̀ níbẹ̀." 23 Mo dìde, mo lọ ibi ó tẹ́. Ògo Olúwa dúró níbẹ̀, ó dàbí irú ògo mo létí odò Kebari, mo dojúbolẹ̀.

24 Nígbà náà ni ̀wọ inú mi, ó tún gbé mi dúró. Ó fún mi , "Lọ, ti ara rẹ mọ́ inú ilé rẹ 25 ṣùgbọ́n ìwọ, ọmọ ènìyàn, wọn yóò fi okùn ́ mọ́lẹ̀; ibi ìwọ í le rìn káàkiri láàrín àwọn ènìyàn. 26 Èmi yóò ahọ́n rẹ lẹ̀ mọ́ àjà ẹnu rẹ, bẹ́̀ ti ìwọ yóò ìdákẹ́ jẹ́́. Ìwọ wọn , ó tilẹ̀ jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ ilé wọn. 27 Ṣùgbọ́n nígbà èmi sọ̀rọ̀, Èmi yóò ṣí lẹ́nu, ìwọ yóò sọ fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè .Ẹni fẹ́ ó gbọ́, ẹni fẹ́ kọ̀, kọ̀ nítorí ọlọ̀tẹ̀ ilé ni wọ́n.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-