Publicidade

Ezequiel 11

Ìdájọ́ lórí àwọn àgbà Israẹli

1 ̀gbé mi sókè, ó mi lọ ẹnu-ọ̀ilé Olúwa èyí dojúkọ ìlà-oòrùn. àbáwọlé ẹnu-ọ̀yìí ni àwọn ọkùnrin mẹ́̀́dọ́gbọ̀n , mo Jaaṣaniah ọmọ Assuri àti Pelatiah ọmọ Benaiah, wọ́n jẹ́ ìjòyè àwọn ènìyàn. 2 Olúwa sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin yìí ń pète ibi, wọ́n ń gbé ìmọ̀ràn búburú kalẹ̀ nínú ìlú. 3 Wọ́n , ha ì àsìkò láti kọ́? Ìlú yìí ni ìkòkò ìdáná, àwa ni ẹran. 4 Nítorí náà sọtẹ́lẹ̀ nípa wọn; ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀."

5 ̀Olúwa mi, ó , "Sọ̀rọ̀!" Báyìí ni Olúwa , ohun ń sọ nìyìí, ilé Israẹli, mo mọ ohun lọ́kàn yín. 6 ̀yin ti sọ òkú yín di púpọ̀ nínú ìlú yìí, òkú ti kún gbogbo ìgboro rẹ̀.

7 "Torí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè , àwọn òkú fọn sílẹ̀ àárín yín ni ẹran, ìlú yìí ni ìkòkò ìdáná ṣùgbọ́n èmi yóò le yín jáde níbẹ̀. 8 bẹ̀idà, èmi yóò idà sórí yín, bẹ́̀ ni Olúwa Olódùmarè . 9 Èmi yóò yín jáde kúrò ìlú yìí, èmi yóò yín àjèjì lọ́wọ́, èmi yóò ìdájọ́ ṣẹ yín lórí. 10 Nípa idà ni ̀yin yóò ṣubú, èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín àwọn ààlà ìlú Israẹli. Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. 11 Ìlú yìí i jẹ́ ìkòkò ìdáná, bẹ́̀ ni ̀yin náà jẹ́ ẹran nínú rẹ̀, Èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín àwọn ààlà ìlú Israẹli. 12 ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa, nítorí ̀yin tẹ̀àṣẹ mi ̀yin pa òfin mi mọ́, ṣùgbọ́n ̀yin ti hùwà gẹ́gẹ́ àwọn aláìgbàgbọ́ orílẹ̀-èdè yín ."

13 mo ṣe ń sọtẹ́lẹ̀ lọ́wọ́, Pelatiah ọmọ Benaiah . Mo dojúbolẹ̀, mo kígbe sókè , "Háà! Olúwa Olódùmarè! Ṣé ìwọ yóò ha pa ìyókù Israẹli run pátápátá ni?"

14 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ , 15 "Ọmọ ènìyàn, àwọn arákùnrin rẹ, àní àwọn ará rẹ, àwọn ọkùnrin nínú ìbátan rẹ, àti gbogbo ilé Israẹli pátápátá, ni àwọn ará Jerusalẹmu ti fún , jìnnà Olúwa, àwa ni a fi ilẹ̀ yìí fún yín ìní.

Ìlérí Israẹli yóò padà

16 "Nítorí náà, sọ fún àwọn ìgbèkùn , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , tilẹ̀ jẹ́ mo ti fọ́n wọn káàkiri orílẹ̀-èdè, síbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀, èmi yóò jẹ́ ibi mímọ́ fún wọn níbi wọ́n lọ.

17 "Nítorí náà, , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , Èmi yóò wọn jọ kúrò láàrín àwọn orílẹ̀-èdè mo fọ́n wọn , Èmi yóò fún wọn ilẹ̀ Israẹli padà.’ 

18 "Wọn yóò padà síbẹ̀, wọn yóò gbogbo àwòrán ìríra rẹ̀ àti ìbọ̀rìṣà rẹ̀ kúrò. 19 11.19: El 18.31; 36.26; 2Kọ 3.3.Èmi yóò fún wọn ̀kankan; èmi yóò fi ̀tuntun sínú wọn, Èmi yóò ọkàn òkúta kúrò lára wọn, èmi yóò fún wọn ọkàn rọ̀ ara ẹran. 20 wọn le tẹ̀àṣẹ mi, wọn le pa òfin mi mọ́. Wọ́n yóò jẹ́ ènìyàn mi, Èmi náà yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn. 21 Ṣùgbọ́n fún àwọn wọ́n ń fi gbogbo ọkàn wọn sin àwọn àwòrán ìríra àti àwọn òrìṣà, Èmi yóò ̀san ohun wọ́n ṣe orí wọn bẹ́̀ ni Olúwa Olódùmarè ."

22 Àwọn kérúbù gbé ìyẹ́ wọn sókè pẹ̀kẹ̀kẹ́ lẹ́gbẹ̀́ wọn, ògo Ọlọ́run Israẹli lókè orí wọn. 23 Ògo Olúwa gòkè lọ kúrò láàrín ìlú, ó dúró lórí òkè ìlà-oòrùn ìlú náà. 24 Lẹ́yìn náà, ̀gbé mi sókè, ó mi Kaldea lójú ìran, nípa ti ̀Ọlọ́run ̀dọ̀ àwọn ti ìgbèkùn.

Bẹ́̀ ni ìran mo lọ kúrò ̀dọ̀ mi, 25 mo sọ gbogbo ohun Olúwa fihàn fún àwọn ìgbèkùn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-