Pular para o conteúdo
Publicidade

Ezequiel 16

36 Báyìí ni Olúwa Olódùmarè , "Nítorí ìwọ ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ jáde, ìwọ fi ìhòhò rẹ hàn, nípa ṣíṣe àgbèrè pẹ̀àwọn olólùfẹ́ rẹ, àti nítorí gbogbo òrìṣà ìríra o fi ̀jẹ̀ àwọn ọmọ rẹ ṣe ìrúbọ fún, 37 nítorí náà, Èmi yóò ṣa gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ jọ, àwọn ẹni ti ìwọ ti jayé àti gbogbo àwọn ìwọ ti fẹ́ àti àwọn ìwọ kórìíra. Èmi yóò sa gbogbo wọn káàkiri jọ, láti wọn lòdì , èmi yóò aṣọ rẹ, níwájú wọn, wọn yóò ìhòhò rẹ.

Veja também