Publicidade

Ezequiel 34

Àwọn olùṣọ́-àgùntàn àti àgùntàn

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ́ mi : 2 "Ọmọ ènìyàn, fi àsọtẹ́lẹ̀ tako Olùṣọ́-àgùntàn Israẹli; sọtẹ́lẹ̀ fún wọn : Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Ègbé ni fún olùṣọ́-àgùntàn Israẹli ó ń tọ́ara wọn nìkan! Ṣé ó dára olùṣọ́-àgùntàn ṣaláì tọ́agbo ẹran? 3 Ìwọ jẹ wàrà. O wọ aṣọ olówùú ara rẹ, o ń pa ẹran ó ́, ṣùgbọ́n ìwọ tọ́agbo ẹran. 4 Ìwọ ì ì aláìlágbára lára le tàbí wo aláìsàn sàn tàbí di ọgbẹ́ fún ẹni o fi ara pa. Ìwọ í ì aṣáko padà tàbí ẹni ó . Ìwọ ṣe àkóso wọn ̀lílé pẹ̀ìwà òǹrorò. 5 Nítorí náà wọn fọ́n káàkiri nítorí àìsí olùṣọ́-àgùntàn, nígbà wọ́n fọ́nká tán wọn di ìjẹ fún gbogbo ẹranko búburú. 6 Àgùntàn mi n rin ìrìn àrè kiri gbogbo àwọn òkè gíga àti òkè kékeré. A fọ́n wọn gbogbo orí ilẹ̀ ẹni kankan wọn.

7 " Nítorí náà, ìwọ olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. 8 Níwọ́n ìgbà mo láààyè Olúwa Olódùmarè , nítorí agbo ẹran mi olùṣọ́-àgùntàn nítorí a kọ̀ wọ́n, wọ́n di ìjẹ fún ẹranko búburú gbogbo àti , nítorí àwọn olùṣọ́-àgùntàn mi ṣe àwárí agbo ẹran mi, ṣùgbọ́n wọn ń ṣe ìtọ́ara wọn dípò ìtọ́agbo ẹran mi, 9 nítorí náà, ̀yin olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. 10 Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi ṣe ìlòdì àwọn Olùṣọ́-àgùntàn, èmi yóò béèrè agbo ẹran mi lọ́wọ́ wọn. Èmi yóò wọn dẹ́kun àti máa darí agbo ẹran mi, àwọn olùṣọ́-àgùntàn náà bọ́ ara wọn mọ́. Èmi yóò gba agbo ẹran mi kúrò ni ẹnu wọn, yóò jẹ́ oúnjẹ fún wọn mọ́.

11 " Nítorí èyí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi fúnra mi yóò àgùntàn mi kiri, èmi yóò ṣe àwárí wọn. 12 Gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn ṣe fojú agbo ẹran rẹ̀ ó fọ́nká nígbà ó pẹ̀wọn, bẹ́̀ ni èmi yóò ṣe fojú àgùntàn mi. Èmi yóò gbá wọn kúrò ni gbogbo ibi wọ́n fọ́nká ni ọjọ́ ìkùùkuu àti òkùnkùn. 13 Èmi yóò wọn jáde kúrò àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn jọ láti inú àwọn ìlú, èmi yóò wọn ilẹ̀ ara wọn. Èmi yóò wọn jẹ ni orí àwọn òkè gíga Israẹli, ni àárín àwọn òkè àti gbogbo ibùdó ilẹ̀ náà. 14 Èmi yóò ṣe ìtọ́wọn pápá oko tútù dáradára, àní orí àwọn òkè gíga ti Israẹli ni yóò jẹ́ ilẹ̀ ìjẹ koríko wọ́n. Níbẹ̀ wọn yóò dùbúlẹ̀ ilẹ̀ ìjẹ koríko dídára, níbẹ̀ wọn yóò jẹun pápá oko tútù ó dara orí òkè ti Israẹli. 15 Èmi fúnra mi yóò darí àgùntàn mi, èmi yóò wọn dùbúlẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè . 16 Èmi yóò ṣe àwárí àwọn ó , èmi yóò àwọn ó ń rin ìrìn àrè kiri padà. Èmi yóò di ọgbẹ́ àwọn ó fi ara pa, èmi yóò fún àwọn aláìlágbára ni okun, ṣùgbọ́n àwọn ó sanra ó ni agbára èmi yóò parun. Èmi yóò ṣe olùṣọ́ àwọn agbo ẹran náà pẹ̀òdodo.

17 " tìrẹ, agbo ẹran mi, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn, àti láàrín àgbò àti ewúrẹ́. 18 Ṣé oúnjẹ jíjẹ pápá oko tútù dídára yín! Ṣé ó jẹ́ dandan fún láti fi ẹsẹ̀ tẹ pápá oko tútù rẹ ó ? Ṣé omi ó tòrò fún yín mímu? Ṣe dandan ni ó fi ẹrẹ̀ ẹsẹ̀ yín? 19 Ṣé dandan ni agbo ẹran mi jẹ́ koríko ti tẹ̀ mọ́lẹ̀, wọn omi wọ́n ti fi ẹsẹ̀ wọn sọ di ẹrẹ̀?

20 " Nítorí náà, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè fún wọn: ó, èmi fúnra mi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn ó sanra àti èyí ó . 21 Nítorí ti ìwọ sún síwájú pẹ̀ìhà àti èjìká, ìwọ kan aláìlágbára àgùntàn pẹ̀ìwo rẹ títí ìwọ fi wọn lọ, 22 Èmi yóò gba agbo ẹran mi , a yóò wọ́n mọ́. Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn. 23 Èmi yóò fi Olùṣọ́-àgùntàn kan ṣe olórí wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi, òun yóò tọ́wọn; òun yóò bọ́ wọn yóò jẹ́ Olùṣọ́-àgùntàn wọn. 24 Èmi Olúwa yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi yóò jẹ́ ọmọ-aládé láàrín wọn. Èmi Olúwa o sọ̀rọ̀.

25 " Èmi yóò májẹ̀àlàáfíà pẹ̀wọn, èmi yóò gba ilẹ̀ náà kúrò lọ́wọ́ ẹranko búburú, wọn o gbé aṣálẹ̀, àgùntàn gbé inú igbó àìléwu. 26 Èmi yóò bùkún wọn àti ibi agbègbè ti ó òkè mi . Èmi yóò rán ̀wààrà òjò ni àkókò; òjò ìbùkún yóò . 27 Àwọn igi igbó yóò èso wọn jáde, ilẹ̀ yóò mu irúgbìn jáde; A yóò ààbò bo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà. Wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa, nígbà mo àwọn ohun ó ṣe okùnfà àjàgà, mo gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ó fi wọ́n ṣe ẹrú. 28 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò wọn ẹrú mọ́, àwọn ẹranko búburú yóò pa wọn mọ́. Wọn yóò gbé ni àìléwu, ṣí ẹni kankan yóò le dẹ́rùbà wọ́n. 29 Èmi yóò pèsè ilẹ̀ ti o oríyìn fún èso rẹ̀ fún wọn, wọn yóò jìyà nípasẹ̀ ìyàn mọ́ ni ilẹ̀ náà tàbí ru ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè. 30 Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ , èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi pẹ̀wọn àti , àwọn ilé Israẹli jẹ́ ènìyàn mi, ni Olúwa Olódùmarè . 31 Ìwọ àgùntàn mi, àgùntàn pápá mi; ni ènìyàn, èmi ni Ọlọ́run rẹ; ni Olúwa Olódùmarè .’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-