Publicidade

Ezequiel 36

23 Èmi yóò fi jíjẹ́ mímọ́ orúkọ ńlá mi, èyí a ti sọ di aláìmọ́ hàn ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè, orúkọ ìwọ ti sọ di aláìmọ́ ni àárín wọn. Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ èmi ni Olúwa, ni Olúwa Olódùmarè , nígbà mo fi ara mi hàn ni mímọ́ nípasẹ̀ yín ni iwájú wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-