Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 36

23 Èmi yóò fi jíjẹ́ mímọ́ orúkọ ńlá mi, èyí a ti sọ di aláìmọ́ hàn ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè, orúkọ ìwọ ti sọ di aláìmọ́ ni àárín wọn. Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ èmi ni Olúwa, ni Olúwa Olódùmarè , nígbà mo fi ara mi hàn ni mímọ́ nípasẹ̀ yín ni iwájú wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também