Publicidade

Ezequiel 36

Àsọtẹ́lẹ̀ kan àwọn òkè Israẹli

1 "Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ àwọn òkè gíga Israẹli o , ̀yin òkè gíga Israẹli gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. 2 Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Àwọn ̀sọ nípa yín , "Háà! Àwọn ibi gíga ìgbàanì ti di ohun ìní wa." 3 Nítorí náà, sọtẹ́lẹ̀ ó , Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Nítorí wọn sọ di ahoro, wọn ń dọdẹ rẹ gbogbo ̀ìwọ ó di ìní fún àwọn orílẹ̀-èdè ó , àti ohun ti àwọn ènìyàn ń sọ ̀rọ̀ ìríra àti ìdíbàjẹ́ , 4 nítorí náà, ̀yin òkè gíga Israẹli gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè, èyí yìí Olúwa Olódùmarè fún àwọn òkè gíga àti àwọn òkè kéékèèké, fún àfonífojì ńlá àti àfonífojì kéékèèké, fún àwọn ibi ìsọdahoro ìparun àti fún àwọn ìlú a ti kọ̀sílẹ̀ a ti àwọn orílẹ̀-èdè ó àyíká fi ṣe ẹlẹ́, 5 èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : ìgbóná ọkàn mo sọ̀rọ̀ àwọn kèfèrí yòókù, àti Edomu, nítorí pẹ̀ìbínú àti ìjowú ọkàn wọn ni wọ́n sọ ilé mi di ohun ìní wọn, wọn o pápá oko tútù rẹ̀.’ 6 Nítorí náà, sọtẹ́lẹ̀ nípa ilẹ̀ Israẹli náà o sọ àwọn òkè gíga náà àti àwọn òkè kéékèèké, àwọn àfonífojì ńlá àti àwọn àfonífojì kéékèèké, Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi sọ̀rọ̀ nínú ìrunú owú mi nítorí ìwọ ti jìyà ìfiṣẹ̀sín àwọn orílẹ̀-èdè. 7 Nítorí náà, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Èmi ṣe ìbúra nípa nína ọwọ́ mi sókè ; àwọn orílẹ̀-èdè àyíká rẹ náà yóò jìyà ìfiṣẹ̀sín.

8 " Ṣùgbọ́n ìwọ, òkè gíga Israẹli, yóò ̀ka àti èso fún àwọn ènìyàn mi Israẹli, nítorí wọn yóò sílé àìpẹ́ yìí. 9 Èmi ń ṣe àníyàn fún , èmi yóò fi rere wọ̀ ́; àwa yóò tu ́, àwa yóò gbìn ́, 10 èmi yóò sọ iye àwọn ènìyàn di púpọ̀ nínú rẹ àti gbogbo ilé Israẹli. Àwọn ìlú yóò di ibùgbé, a yóò tún àwọn ibi ìparun kọ́. 11 Èmi yóò sọ iye ènìyàn àti ẹran púpọ̀ nínú yín, wọn yóò so èso, wọn yóò di púpọ̀ yanturu. Èmi yóò àwọn ènìyàn máa gbé nínú rẹ ti àtẹ̀yìnwá, èmi yóò o ṣe rere ju ìgbà àtijọ́ lọ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ èmi ni Olúwa. 12 Èmi yóò àwọn ènìyàn, àní àwọn ènìyàn Israẹli, rìn lórí rẹ̀. Wọn yóò gbà ́, ìwọ yóò di ogún ìní wọn; ìwọ yóò gba àwọn ọmọ wọn lọ́wọ́ wọn mọ́.

13 " Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Nítorí àwọn ènìyàn sọ fún , "Ìwọ pa àwọn ènìyàn run, ìwọ gba àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè lọ́wọ́ wọn," 14 nítorí náà ìwọ yóò pa àwọn ènìyàn run tàbí orílẹ̀-èdè di aláìlọ́mọ mọ́, ni Olúwa Olódùmarè . 15 Èmi yóò ki ó gbọ́ ̀rọ̀ ̀gàn láti ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mọ́, ìwọ yóò jìyà ̀rọ̀ ìfiṣẹ̀sín láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tàbí orílẹ̀-èdè rẹ ṣubú, ni Olúwa Olódùmarè .’ "

16 Síwájú i ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 17 "Ọmọ ènìyàn, nígbà àwọn ènìyàn Israẹli ń gbé ilẹ̀ wọn, wọ́n á jẹ́ nípa ìwà àti ìṣe wọn. Ìwà wọn dàbí nǹkan àkókò àwọn obìnrin ni ojú mi. 18 Nítorí náà mo ìbínú mi jáde sórí wọn nítorí wọn ti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀ àti nítorí wọ́n ti fi ère wọn ba a jẹ́. 19 Mo wọn àárín àwọn orílẹ̀-èdè, a fọ́n wọn àwọn ìlú; mo ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ ìwà àti ìṣe wọn. 20 Gbogbo ibi wọ́n lọ àárín àwọn orílẹ̀-èdè ni wọn ti sọ orúkọ mímọ́ mi di aláìmọ́, nítorí a sọ nípa wọn , Ìwọ̀nyí ni àwọn ènìyàn Olúwa, síbẹ̀ wọn láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀.’ 21 Orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mi lógún, èyí ilé Israẹli sọ di aláìmọ́ ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n ti lọ.

22 "Nítorí náà, sọ fún ilé Israẹli, Èyí ni Olúwa Olódùmarè : í ṣe nítorí rẹ, ìwọ ilé Israẹli, ni èmi yóò ṣe ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí, ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mímọ́ mi, èyí ti ìwọ ti sọ di aláìmọ́ àárín àwọn orílẹ̀-èdè ìwọ ti lọ. 23 Èmi yóò fi jíjẹ́ mímọ́ orúkọ ńlá mi, èyí a ti sọ di aláìmọ́ hàn ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè, orúkọ ìwọ ti sọ di aláìmọ́ ni àárín wọn. Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ èmi ni Olúwa, ni Olúwa Olódùmarè , nígbà mo fi ara mi hàn ni mímọ́ nípasẹ̀ yín ni iwájú wọn.

24 " Nítorí èmi yóò yín jáde kúrò ni àwọn orílẹ̀-èdè náà; Èmi yóò ṣà yín jọ kúrò gbogbo àwọn ìlú náà; Èmi yóò yín padà ilẹ̀ ̀yin tìkára yín. 25 Èmi yóò wọ́n omi mọ́ yín lára ̀yin yóò mọ́; Èmi yóò fọ̀ yín mọ́ kúrò nínú gbogbo ìwà èérí yin gbogbo àti kúrò nínú gbogbo òrìṣà yin. 26 Èmi yóò fún yín ni ọkàn tuntun, èmi yóò fi ̀tuntun sínú yín; Èmi yóò ọkàn òkúta kúrò nínú yín, èmi yóò fi ọkàn ẹran fún yín. 27 Èmi yóò fi ̀mi sínú yín, èmi yóò ki tẹ̀àṣẹ mi, fiyèsí àti pa òfin mi mọ́. 28 ̀yin yóò máa gbé ilẹ̀ náà mo ti fi fún àwọn baba ńlá yín; ̀yin yóò jẹ́ ènìyàn mi èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run yín. 29 Èmi yóò gbà yín kúrò nínú gbogbo ìwà àìmọ́ yín. Èmi yóò pèsè ọkà, èmi yóò ó pọ̀ yanturu, èmi yóò ìyàn orí yín. 30 Èmi yóò sọ èso àwọn igi yín àti ohun ̀gbìn oko yín di púpọ̀, nítorí ̀yin ó ṣe jìyà ìdójútì mọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà nítorí ìyàn. 31 Nígbà náà ni ̀yin yóò rántí àwọn ̀búburú àti àwọn ìwà ìkà yín, ̀yin yóò kórìíra ara yín fún ̀ṣẹ̀ yín, ìwà bójúmu. 32 Mo fẹ́ mọ̀ ń ṣe nǹkan wọ̀nyí nítorí yín, ni Olúwa Olódùmarè . Jẹ ojú ó yín, gba ̀tẹ́ nítorí ìwà yín ̀yin ilé Israẹli!

33 " Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : ọjọ́ mo wẹ̀ yín kúrò nínú ̀ṣẹ̀ yín gbogbo, èmi yóò ṣe àtúnṣe àwọn ìlú yín, wọn yóò ṣe àtúnkọ́ ìwólulẹ̀. 34 Ilẹ̀ ahoro náà àwa yóò tún kọ́ ti yóò ahoro lójú àwọn ó ń gba ibẹ̀ kọjá mọ́. 35 Wọn yóò sọ , "Ilẹ̀ yìí ó ti ahoro tẹ́lẹ̀ ti dàbí ọgbà Edeni; àwọn ìlú ó wíwó lulẹ̀, ahoro a ti parun, ni àwa yóò mọdi yóò fún gbígbé ni ìsinsin yìí." 36 Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè ó àyíká yín ó yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ti tún àwọn ohun ó bàjẹ́ kọ́, mo ti tún ohun ó di ìṣòfo gbìn. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, èmi yóò ṣe e?

37 "Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè sọ: Lẹ́̀kan i èmi yóò ilé Israẹli, èmi yóò ṣe èyí fún wọn. Èmi yóò àwọn ènìyàn yín pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ àgùntàn, 38 ó pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ̀wọ́ ẹran fún ìrúbọ Jerusalẹmu àsìkò àjọ̀dún a yàn. Ìlú ti a parun yóò kún fún agbo àwọn ènìyàn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-