Publicidade

Ezequiel 37

Àfonífojì àwọn egungun gbígbẹ

1 Ọwọ́ Olúwa lára mi, ó mi jáde pẹ̀̀Olúwa, ó ń àárín àfonífojì; ti o kún fún àwọn egungun. 2 Ó mi lọ síwájú àti sẹ́yìn láàrín wọn, èmi ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn egungun orí ilẹ̀ àfonífojì, àwọn egungun ó gbẹ gan. 3 Olúwa bi léèrè, "Ọmọ ènìyàn, ǹjẹ́ àwọn egungun wọ̀nyí yípadà di àwọn ènìyàn ?"

Èmi , "Ìwọ Olúwa Olódùmarè, ìwọ nìkan ni o dáhùn ìbéèrè yìí."

4 Nígbà náà ni ó fún mi , "Sọtẹ́lẹ̀ àwọn egungun ó sọ fún wọn , ̀yin egungun gbígbẹ gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa! 5 37.5,10: If 11.11.Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè fún àwọn egungun wọ̀nyí. Èmi yóò èémí wọ inú yín ̀yin yóò di ààyè. 6 Èmi yóò so iṣan ara mọ́ ọn yín, Èmi yóò ẹran-ara ara yín, Èmi yóò fi awọ ara yín, Èmi yóò fi èémí sínú yín, ̀yin yóò ààyè. Nígbà náà ̀yin yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.’ "

7 Nítorí náà ni mo ṣe sọtẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ a ti pa á láṣẹ fún mi. mo ti ń sọtẹ́lẹ̀, ariwo , ìró ó kígbe sókè, àwọn egungun papọ̀, egungun egungun. 8 Mo ó, iṣan ara àti ẹran-ara farahàn lára wọn, awọ ara wọ́n, ṣùgbọ́n èémí nínú wọn.

9 Lẹ́yìn náà ni ó sọ fún mi , "Sọtẹ́lẹ̀ èémí; sọtẹ́lẹ̀, ọmọ ènìyàn, ó sọ fún un , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : láti atẹ́gùn mẹ́rẹ̀̀rin, ìwọ èémí, ó èémí sínú àwọn a pa wọ̀nyí, wọn ó ààyè.’ " 10 Nítorí náà, mo sọtẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ ó ṣe pa á láṣẹ fún mi, èémí wọ inú wọn; wọ́n di alààyè, wọ́n dìde dúró lórí ẹsẹ̀ wọnpẹ̀ìhámọ́ra ó pọ̀.

11 Lẹ́yìn náà ó sọ fún mi: "Ọmọ ènìyàn, àwọn egungun wọ̀nyí ni gbogbo ìdílé Israẹli. Wọ́n sọ , Egungun wa ti gbẹ ìrètí wa ti lọ; a ti wa kúrò.12 Nítorí náà sọtẹ́lẹ̀, o sọ fun wọn , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè sọ: ̀yin ènìyàn mi, Èmi yóò ṣí àwọn ibojì yín, èmi yóò yín si ilẹ̀ Israẹli. 13 ̀yin o mọ̀ èmi ni Olúwa, nígbà èmi ti ṣí ibojì yín, ̀yin ènìyàn mi, ti èmi si un yín dìde kúrò nínú ibojì yín. 14 37.14: El 36.27; 1Tẹ 4.8.Èmi yóò fi èémí mi sínú yín, ̀yin yóò , èmi yóò fi lélẹ̀ ilẹ̀ ̀yin tìkára yín. Nígbà náà ̀yin yóò mọ̀ Olúwa ti sọ̀rọ̀, èmi ti ṣe ni Olúwa .’ "

Orílẹ̀-èdè kan abẹ́ ọba kan

15 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mi : 16 "Ọmọ ènìyàn, igi pátákó kan ó kọ̀ara rẹ̀, ó jẹ́ ti Juda àti ti Israẹli ó àṣepọ̀ pẹ̀rẹ̀.’ Lẹ́yìn náà, ó igi pátákò mìíràn ó kọ̀ara rẹ̀, ó jẹ́ ti Josẹfu (ó túmọ̀ ti Efraimu) àti gbogbo ilé Israẹli ó ni àṣepọ̀ pẹ̀rẹ̀.’ 17 So wọ́n papọ̀ ara igi kan nítorí náà wọn yóò di ̀kan ọwọ́ rẹ.

18 "Nígbà àwọn ara ìlú rẹ béèrè lọ́wọ́ rẹ , Ṣé ìwọ sọ ohun èyí túmọ̀ fún wa?19 Sọ fún wọn , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò gba igi Josẹfuèyí ó ọwọ́ Efraimuàti ti ̀Israẹli ó parapọ̀ mọ́ ọn, ó papọ̀ mọ́ igi Juda, láti sọ wọ́n di igi kan ṣoṣo, wọn yóò di ̀kan ọwọ́ mi.20 Gbé igi pátákó ó kọ nǹkan i sókè iwájú wọn, 21 ó sọ fún wọn , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò Israẹli jáde kúrò àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n ti lọ. Èmi yóò ṣà wọ́n jọ pọ̀ láti gbogbo agbègbè, èmi yóò wọn padà ilẹ̀ ara wọn. 22 Èmi yóò ṣe wọ́n orílẹ̀-èdè kan ilẹ̀ náà, orí òkè Israẹli, ọba kan ni yóò lórí gbogbo wọn, wọn yóò jẹ́ orílẹ̀-èdè méjì mọ́, tàbí a pín wọn ìjọba méjì. 23 Wọn yóò tún fi àwọn òrìṣà wọn ba ara wọn jẹ́ mọ́, tàbí ohun ìríra wọn, tàbí ohun ìrékọjá wọn: ṣùgbọ́n èmi yóò gbà wọn kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ àgàbàgebè wọn, èmi yóò wẹ̀ wọn mọ́. Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn.

24 " Dafidi ìránṣẹ́ mi ni yóò jẹ ọba lórí wọn, gbogbo wọn yóò olùṣọ àgùntàn kan. Wọn yóò tẹ̀òfin mi, wọn yóò ṣe àníyàn láti pa àṣẹ mi mọ́. 25 Wọn yóò gbé ilẹ̀ mo fún Jakọbu ìránṣẹ́ mi, ilẹ̀ àwọn baba yín ń gbé. Àwọn àti àwọn ọmọ wọn àti àwọn ọmọ ọmọ wọn ni yóò máa gbé ibẹ̀ láéláé, ìránṣẹ́ mi Dafidi ni yóò jẹ́ Ọmọ-aládé wọn láéláé. 26 37.26: Hb 13.20.Èmi yóò májẹ̀àlàáfíà pẹ̀wọn, yóò jẹ́ májẹ̀títí ayérayé. Èmi yóò gbé wọn kalẹ̀, èmi yóò sọ wọ́n di púpọ̀ iye, èmi yóò gbé ilé mímọ́ mi kalẹ̀ àárín wọn títí láé. 27 37.27: Ek 25.8; 29.45; Le 26.12; Jr 31.1; 2Kọ 6.16; If 21.3.Ibùgbé yóò pẹ̀wọn, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn, wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi. 28 Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ , Èmi Olúwa sọ Israẹli di mímọ́, nígbà ibi mímọ́ mi àárín wọn títí ayérayé.’ "

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-