Publicidade

Ezequiel 38

Àsọtẹ́lẹ̀ kan Gogi

1 Ọrọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ Gogu, ti ilẹ̀ Magogu; olórí ọmọ-aládé, Meṣeki, àti Tubali sọtẹ́lẹ̀ ìlòdì i 3 ó , Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Èmi lòdì , ìwọ Gogu, olórí ọmọ-aládé, Meṣeki àti Tubali. 4 Èmi yóò kiri, èmi yóò fi ìwọ̀ kọ́ ẹnu, èmi yóò ́ jáde pẹ̀gbogbo ọmọ-ogun rẹ, àwọn ẹṣin àti àwọn agẹṣinjagun nínú ìhámọ́ra, àti ìpéjọ ńlá pẹ̀asà ogun ńlá àti kéékèèké, gbogbo wọn ń fi idà wọn. 5 Persia, Kuṣi àti Puti yóò pẹ̀wọn, gbogbo wọn yóò pẹ̀asà àti ìṣíborí wọn 6 Gomeri náà pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti Beti-Togarma láti jìnnàjìnnà àríwá pẹ̀gbogbo àwọn ̀wọ́ ogun rẹ̀—̀pọ̀lọpọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀rẹ̀.

7 " Múra sílẹ̀, múra tán, ìwọ àti gbogbo ìjọ náà péjọpọ̀ pẹ̀rẹ, o pàṣẹ fún wọn. 8 Lẹ́yìn ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́, àwa yóò bẹ̀ ; ọdún ìkẹyìn ìwọ yóò ti ilẹ̀ a ti gbà padà lọ́wọ́ idà, àwọn ènìyàn wọn kórajọ pọ̀ láti ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè àwọn òkè gíga ti Israẹli, ó ti di ahoro fún ìgbà pípẹ́. A ti wọn jáde láti ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè, nísinsin yìí gbogbo wọn ń gbé àìléwu. 9 Ìwọ àti ̀wọ́ ogun rẹ àti ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀rẹ yóò gòkè, ̀yin yóò tẹ̀síwájú ìjì; ìwọ yóò dàbí ìkùùkuu ó bo ilẹ̀ mọ́lẹ̀.

10 " Èyí ni Olúwa Olódùmarè : ọjọ́ náà èrò kan yóò sọ́kàn rẹ, ìwọ yóò pète ìlànà búburú. 11 Ìwọ yóò , "Èmi yóò gbé ogun ti ilẹ̀ àwọn a fi odi yíká, Èmi yóò gbé ogun ti àwọn ènìyàn àlàáfíà a funra gbogbo wọn ń gbé àìsí odi, àìsí ẹnu-ọ̀òde àti àsígbè-irin. 12 Èmi yóò ohun ọdẹ, èmi yóò ìkógun, èmi yóò ọwọ́ mi padà ibi ìwólulẹ̀ ti a ti tún kọ́, àwọn ènìyàn a kójọpọ̀ láti ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè, ó ọrọ̀ nínú ẹran ̀sìn àti ẹrú, ó ń gbé àárín gbùngbùn ilẹ̀ náà." 13 Ṣeba, Dedani àti àwọn oníṣòwò Tarṣiṣi àti gbogbo àwọn ọmọ kìnnìún wọn, yóò sọ fún un yín , "Ṣé ̀yin fún ìkógun? Ṣé ̀yin ti àwọn ogun yín jọ pọ̀ fún ìkógun, láti fàdákà àti wúrà lọ, láti ẹran ̀sìn àti ẹrú àti láti gba ̀pọ̀ ìkógun?" ’ "

14 "Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ ó sọ fún Gogu: Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : ọjọ́ náà, nígbà àwọn ènìyàn mi Israẹli ń gbé àìléwu, ìwọ yóò ha ṣe àkíyèsí rẹ̀? 15 Ìwọ yóò láti ààyè rẹ jìnnàjìnnà àríwá, ìwọ àti ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀rẹ, gbogbo wọn yóò gun ẹṣin ẹgbẹ́ ńlá, jagunjagun alágbára. 16 Ìwọ yóò tẹ̀síwájú ìlòdì àwọn Israẹli ènìyàn mi gẹ́gẹ́ ìkùùkuu ó bo ilẹ̀. Ni àwọn ọjọ́ ń bọ̀, ìwọ Gogu, èmi yóò ìlòdì ilẹ̀ mi, àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ mi nígbà mo fi ara hàn ni mímọ́ láti ̀dọ̀ rẹ ojú wọn.

17 " Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè : Ìwọ ha kọ́ ni mo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ ìgbà ìṣáájú láti ẹnu àwọn wòlíì ìránṣẹ́ mi ti Israẹli? ìgbà náà wọ́n sọtẹ́lẹ̀ fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún èmi yóò lòdì wọn. 18 Èyí ni ohun yóò ṣẹlẹ̀ ọjọ́ náà, nígbà Gogu kọlu ilẹ̀ Israẹli, gbígbóná ìbínú mi yóò ru sókè, ni Olúwa Olódùmarè . 19 ìtara mi àti gbígbóná ìbínú mi, mo tẹnumọ́ ọn ; àsìkò náà ilẹ̀ mímì ó lágbára ilẹ̀ Israẹli yóò ṣẹlẹ̀. 20 Ẹja inú Òkun, àwọn ẹyẹ òfúrufú, àwọn ẹranko igbó, àti gbogbo ̀ó ń rìn lórí ilẹ̀ yóò wárìrì fún ìfarahàn mi. A yóò òkè gíga po, àwọn bèbè òkúta ni àwa yóò fọ́ wẹ́wẹ́, gbogbo ògiri ni yóò palẹ̀. 21 Èmi yóò fa idà yọ ni ìlòdì Gogu orí gbogbo àwọn òkè gíga mi ni Olúwa Olódùmarè . Idà gbogbo ènìyàn yóò lòdì arákùnrin rẹ̀. 22 Èmi yóò gbé ìdájọ́ mi jáde lórí rẹ̀ pẹ̀ìyọnu àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀, Èmi yóò àgbàrá òjò, òkúta yìnyín àti imí-ọjọ́ ń e lórí àti lórí ̀wọ́ ogun àti lórí ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀rẹ̀. 23 Nítorí náà, Èmi yóò fi títóbi mi àti ìjẹ́-mímọ́ mi hàn, Èmi yóò fi ara mi hàn ojú ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-