Pular para o conteúdo
Publicidade

Ezequiel 39

1 "Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ Gogu, ó : Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Èmi lòdì , Ìwọ Gogu, olórí ọmọ-aládé ti Meṣeki àti Tubali. 2 Èmi yóò padà, èmi yóò darí rẹ. Èmi yóò láti jìnnàjìnnà ìhà àríwá, Èmi yóò rán lòdì orí àwọn òkè gíga Israẹli. 3 Nígbà náà èmi yóò lu ọrùn awọ rẹ ọwọ́ òsì rẹ, èmi yóò àwọn ọfà rẹ jábọ́ ni ọwọ́ ̀tún rẹ. 4 39.4,17-20: If 19.17,18,21.Ìwọ yóò ṣubú orí àwọn òkè Israẹli, ìwọ àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ àti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ó pẹ̀rẹ. Èmi yóò fi ṣe oúnjẹ fún àwọn onírúurú ẹyẹ àti fún àwọn ẹranko igbó. 5 Ìwọ yóò ṣubú gbangba pápá, nítorí mo ti sọ̀rọ̀, ni Olúwa Olódùmarè . 6 Èmi yóò fi iná Magogu àti àwọn ń gbé agbègbè ilẹ̀ ibẹ̀ àìléwu, wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

7 " Èmi yóò sọ orúkọ mímọ́ di mọ̀ láàrín àwọn ènìyàn Israẹli. Èmi ki yóò jẹ́ orúkọ mímọ́ mi di aláìmọ́ àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ , Èmi Olúwa, Èmi ni ẹni mímọ́ Israẹli. 8 Ó ń bọ̀! Ó dájú yóò ṣẹlẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè. Èyí yìí ni ọjọ́ mo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀.

9 " Nígbà náà, àwọn ti ó ń gbé àárín àwọn ìlú ó ni Israẹli yóò jáde, wọn yóò lo àwọn ohun ìjà bi epo ìdáná yóò wọ́n kanlẹ̀—àpáta kéékèèké àti àpáta ńlá, àwọn ọfà, àwọn kùmọ̀ ogun àti ̀kọ̀ fún ọdún méje wọn yóò wọ́n bi epo ìdáná. 10 Wọn nílò láti igi jọ láti inú pápá, tàbí e láti inú igbó, nítorí wọ́n yóò lo òhun ìjà ogun bi epo ìdáná. Wọn yóò kógun àwọn ó ṣe ìgárá wọn, wọn yóò bo ilé àwọn ó bo ilé wọn, ni Olúwa Olódùmarè.

11 " ọjọ́ náà èmi yóò fi ibi ìsìnkú fún Gogu Israẹli, ni àfonífojì àwọn ti ó rìn ìrìnàjò lọ agbègbè ilà oòrùn Òkun. Yóò di ojú ̀àwọn arìnrìn-àjò, nítorí Gogu àti gbogbo ìjọ rẹ̀ ni àwa yóò sin síbẹ̀. Nítorí náà, a yóò é àfonífojì Ammoni Gogu.

12 " Fún oṣù méje ilé Israẹli yóò fi máa sìn wọ́n láti ṣe àfọ̀mọ́ ilẹ̀ náà. 13 Gbogbo ènìyàn ilẹ̀ náà yóò sìn wọ́n, ọjọ́ a yìn mi lógo yóò jẹ́ ọjọ́ ìrántí, Olúwa Olódùmarè .

14 " Wọn yóò gbà àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́ lóòrèkóòrè láti ṣe àfọ̀mọ́ náà. ̀pọ̀ yóò lọ káàkiri ilẹ̀ náà, àfikún pẹ̀wọn, àwọn tókù yóò sìn àwọn ó lórí ilẹ̀. ìparí oṣù keje wọn yóò bẹ̀rẹ̀ wíwá kiri wọn. 15 wọ́n n lọ káàkiri ilẹ̀ náà ̀kan nínú wọn egungun ènìyàn, òun yóò gbé àmì ńlá kalẹ̀ ni ̀gbẹ́ rẹ títí àwọn asìnkú yóò fi sìn ín àfonífojì Hamoni Gogu. 16 Bákan náà ìlú kan a ń ni Hamona yóò níbẹ̀. Nítorí náà wọn yóò wẹ ilẹ̀ náà.

17 "Ọmọ ènìyàn èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè , pe gbogbo oríṣìíríṣìí ẹyẹ àti gbogbo àwọn ẹranko igbó jáde, wọn péjọpọ̀ láti gbogbo agbègbè ìrúbọ ń múra rẹ̀ fún , ìrúbọ ńlá náà orí òkè gíga Israẹli. Níbẹ̀ ̀yin yóò jẹ ẹran, ̀yin yóò ̀jẹ̀. 18 ̀yin yóò jẹ ẹran-ara àwọn ènìyàn ńlá, o ̀jẹ̀ àwọn ọmọ-aládé ayé ẹni wọn jẹ́ àgbò àti ̀dọ́-àgùntàn, ewúrẹ́ àti akọ màlúù gbogbo wọn jẹ́ ẹran ọlọ́ràá láti Baṣani. 19 Níbi ìrúbọ mo ń múra kalẹ̀ fún yín, ̀yin yóò jẹ ̀títí ̀yin yóò fi jẹ àjẹkì, ̀yin yóò ̀jẹ̀ títí ̀yin yóò fi . 20 orí tábìlì mi ni àwa yóò ti fi ẹṣin àti ẹlẹ́ṣin bọ yín , pẹ̀àwọn alágbára ńlá àti oríṣìíríṣìí jagunjagun,ni Olúwa Olódùmarè .

21 "Èmi yóò ṣe àfihàn ògo mi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, gbogbo orílẹ̀-èdè yóò ìyà mo fi jẹ wọ́n. 22 Láti ọjọ́ náà lọ, ilé Israẹli yóò mọ̀ èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn. 23 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ àwọn ènìyàn Israẹli lọ ìgbèkùn nítorí ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ mi. Nítorí náà mo ojú mi pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn, mo fi wọn àwọn ̀wọn lọ́wọ́, gbogbo wọn ṣubú nípasẹ̀ idà. 24 Mo ṣe wọn gẹ́gẹ́ àìmọ́ àti àìṣedéédéé wọn, mo ojú mi pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn.

25 "Nítorí náà èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè : Èmi yóò Jakọbu padà kúrò oko ẹrú, èmi yóò ìyọ́si gbogbo ènìyàn Israẹli, èmi yóò ìtara fún orúkọ mímọ́ mi. 26 Wọn yóò gbàgbé ìtìjú wọn àti gbogbo àìṣòdodo wọ́n fihàn mi nígbà wọn ń gbé ni àìléwu ni ilẹ̀ wọn níbi ti ẹnikẹ́ni láti dẹ́rùbà wọ́n. 27 Nígbà mo ti wọn padà kúrò àwọn orílẹ̀-èdè, mo wọn jọ pọ̀ kúrò ni ìlú àwọn ̀wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ni mímọ́ nípasẹ̀ wọn ojú àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀. 28 Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn nítorí ó tilẹ̀ jẹ́ mo rán wọn lọ ìgbèkùn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn jọ orí ilẹ̀ wọn, láìfi nǹkan kan sẹ́yìn. 29 Èmi yóò fi ojú mi pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn mọ nítorí èmi yóò èémí mi jáde ilé Israẹli, Olúwa Olódùmarè ."

Veja também