Publicidade

Ezequiel 47

Odò láti inú tẹmpili náà

1 47.1-2: Sk 14.8; If 22.1-2. Ọkùnrin náà mi padà lọ àbáwọlé tẹmpili náà, mo omi ó ń jáde láti abẹ́ ìloro tẹmpili náà apá ìhà ìlà-oòrùn (nítorí tẹmpili náà dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn). Omi náà ń jáde ìsàlẹ̀ láti abẹ́, ìhà gúúsù tẹmpili náà, ìhà gúúsù pẹpẹ. 2 Ó mi gba ojú ̀àríwá jáde, ó mi ìta ojú ̀ìta ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn, omi náà ń sàn láti ìhà gúúsù .

3 ọkùnrin náà ti lọ apá ìhà ìlà-oòrùn pẹ̀okùn wíwọ̀n nǹkan lọ́wọ́ rẹ̀, ó wọn ẹgbẹ̀rún (1,000) ìgbọ̀nwọ́, ó mi gba ibi odò kan kókósẹ̀ lọ. 4 Ó wọn ẹgbẹ̀rún ìgbọ̀nwọ́ mìíràn kúrò, ó mi gba ibi odò ó ìwọ̀n orúnkún. Ó tún wọn ẹgbẹ̀rún márùn-ún ìgbọ̀nwọ́ mìíràn kúrò, ó mi gba odò ó ìbàdí. 5 Ó wọn ẹgbẹ̀rún ìgbọ̀nwọ́ mìíràn kúrò, ṣùgbọ́n nísinsin yìí odò ń kọjá rẹ̀ ni, nítorí odò ó kún, ó èyí wọ́n le lúwẹ̀́ nínú rẹ̀ odò ẹnikẹ́ni le kọjá ni. 6 Ó bi léèrè , "Ọmọ ènìyàn, ǹjẹ́ o èyí?"

Lẹ́yìn náà, ó mi padà etí odò. 7 Nígbà mo ibẹ̀, mo ̀pọ̀lọpọ̀ igi ̀gbẹ́ méjèèjì odò. 8 Ó sọ fún mi , "Odò yìí ń jáde ìhà ìlà-oòrùn, wọ́n ń sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀tẹ́lẹ̀, wọ́n wọ inú Òkun lọ, a omi wọn láradá. 9 Àwọn ohun alààyè ó ń rákò yóò máa gbé ibikíbi odò ti ń sàn. Ẹja yóò pọ̀ ni ̀pọ̀lọpọ̀, nítorí odò ń sàn síbẹ̀, ó omi iyọ̀ tutù nini; nítorí náà níbi omi ti ń sàn, gbogbo nǹkan ni yóò ni ààyè. 10 Àwọn apẹja yóò dúró etí bèbè odò; láti En-Gedi títí En-Eglaimu ààyè yóò wa láti tẹ́ àwọ̀n wọn sílẹ̀. Oríṣìíríṣìí ẹja ni yóò gẹ́gẹ́ ẹja omi Òkun ńlá. 11 Ṣùgbọ́n ẹrẹ̀ àti àbàtà tòrò; àwa yóò fi wọn sílẹ̀ fún iyọ̀. 12 Àwọn igi eléso oríṣìíríṣìí ni yóò máa bèbè odò ìhà ìhín àti ìhà ̀hún. Ewé wọn yóò rọ, bẹ́̀ èso wọn yóò run, wọn yóò máa ṣe èso tuntun rẹ̀ oṣù nítorí omi láti ibi mímọ́ ń sàn wọn. Èso wọn yóò jẹ́ fún jíjẹ àti ewé wọn fún ìwòsàn."

Àwọn ààlà ilẹ̀ náà

13 Èyí yìí ohun Olúwa Olódùmarè : "Ìwọ̀nyí ni àwọn ààlà ìwọ yóò fi pín ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ ogún ìní àárín àwọn ̀méjìlá Israẹli, pẹ̀ìpín méjì fún Josẹfu. 14 Ìwọ yóò pín ilẹ̀ náà déédé àárín wọn. Nítorí mo búra nípa nína ọwọ́ sókè láti fi fún àwọn baba ńlá yin, ilẹ̀ yìí yóò di ogún ìní yín.

15 "Èyí yìí ni yóò jẹ́ ààlà ilẹ̀ náà:

"ìhà àríwá yóò lọ láti omi Òkun ńlá ibi ̀Hetiloni gbà Hamati lọ Sedadi, 16 Berota àti Sibraimu, èyí ó ààlà láàrín Damasku àti Hamati títí Hasari Hatikonu, èyí ó agbègbè Haurani. 17 Ààlà yóò fẹ̀ láti Òkun lọ Hasari Enanu, apá ààlà ti Damasku, pẹ̀ààlà Hamati lọ apá àríwá. Èyí ni yóò jẹ́ ààlà apá ìhà àríwá.

18 ìhà ìlà-oòrùn ààlà yóò àárín Haurani àti Damasku, lọ apá Jordani láàrín Gileadi àti ilẹ̀ Israẹli, títí Òkun, àti títí Tamari. Èyí yóò jẹ́ ààlà ìlà-oòrùn.

19 ìhà gúúsù yóò lọ láti Tamari títí ibi omi Meriba Kadeṣi, lẹ́yìn náà ni ìhà Wadi Ejibiti lọ Òkun ńlá. Èyí ni yóò jẹ́ ààlà gúúsù.

20 ìhà ìwọ̀-oòrùn, Òkun ńlá ni yóò jẹ́ ààlà títí ibi kan ni òdìkejì lẹ́bàá Hamati. Èyí yìí ni yóò jẹ ààlà ìhà ìwọ̀-oòrùn.

21 "Ìwọ láti pín ilẹ̀ yìí àárín ara yín gẹ́gẹ́ àwọn ̀Israẹli. 22 Ìwọ yóò pín gẹ́gẹ́ ìní fún ara yín àti fún àwọn àjèjì ó ń gbé àárín yín ó àwọn ọmọ. Ìwọ yóò ṣe wọn gẹ́gẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ àwọn ará Israẹli; papọ̀ mọ́ yin ni pín ìní fún wọn àárín àwọn ̀Israẹli. 23 àárín gbogbo ̀àwọn àlejò ń gbé; wọn gbọdọ̀ fi ìní tirẹ̀ fún un," Olúwa Olódùmarè .

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-