Publicidade

Jeremias 18

ilé amọ̀kòkò

1 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Jeremiah pe: 2 "Sọ̀kalẹ̀ lọ ilé amọ̀kòkò, níbẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀rọ̀." 3 Nígbà náà ni mo lọ ilé amọ̀kòkò mo i ó ń ṣiṣẹ́ kan lórí kẹ̀kẹ́. 4 Ṣùgbọ́n ìkòkò ó ń mọ láti ara amọ̀ bàjẹ́ ọwọ́ rẹ̀, nítorí náà ni amọ̀kòkò fi ṣe ìkòkò mìíràn, ó mọ ́n èyí ó dára ojú rẹ̀.

5 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 6 "Ẹyin ilé Israẹli, èmi ha ṣe fún un yín gẹ́gẹ́ amọ̀kòkò yìí ti ṣe?" ni Olúwa . "Gẹ́gẹ́ amọ̀ ọwọ́ amọ̀kòkò bẹ́̀ ni ̀yin ọwọ́ mi, ̀yin ilé Israẹli. 7 ó jẹ́ ìgbà kan, èmi kéde orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan di fífà tu láti dojúdé àti láti parun, 8 orílẹ̀-èdè ti mo kìlọ̀ fún yípadà kúrò nínú ìwà búburú wọn, nígbà náà ni Èmi yóò ọkàn mi padà nínú àjálù mo ti láti ṣe wọn. 9 ìgbà mìíràn èmi tún kéde láti tẹ̀tàbí gbin orílẹ̀-èdè kan tàbí ìjọba kan. 10 ó ṣe búburú níwájú mi, gba ohùn mi gbọ́, nígbà náà ni èmi yóò ọkàn mi padà ti rere, èyí mo , èmi ó ṣe fún wọn.

11 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, sọ fún àwọn ènìyàn Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu , Báyìí Olúwa : ó! Èmi ń gbèrò ibi yin, èmi ń ṣe ìpinnu kan lórí yín. Nítorí náà yípadà kúrò lọ́búburú yín olúkúlùkù yín tún ̀àti ìṣe rẹ̀ ṣe.12 Ṣùgbọ́n wọn yóò sọ , ṣe nǹkan kan, àwa yóò tẹ̀síwájú nínú èrò wa, ẹnìkọ̀̀kan wa, yóò hùwà agídí ọkàn búburú rẹ̀.’ "

13 Nítorí náà báyìí ni Olúwa :

"béèrè nínú orílẹ̀-èdè,

ẹni ó ti gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí ri?

Ohun ó burú gidi ni wúńdíá Israẹli ti ṣe.

14 Ǹjẹ́ omi ojo dídì Lebanoni

yóò ha láti máa sàn láti ibi àpáta?

Tàbí odò ó jìnnà, ó tútù,

ó ń sàn, yóò ha gbẹ ?

15 Nítorí àwọn ènìyàn mi gbàgbé mi,

wọ́n sun tùràrí fún òrìṣà asán,

ó wọn kọsẹ̀ ̀wọn,

àti ̀wọn àtijọ́.

Wọ́n wọn rìn ̀àtijọ́,

àti ojú ̀ti a ṣe.

16 Ilẹ̀ wọn yóò lásán yóò di

nǹkan ̀gàn títí láé,

gbogbo àwọn ó ń kọjá yóò bẹ̀,

wọn yóò mi orí wọn.

17 Gẹ́gẹ́ afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn,

Èmi yóò wọn lójú àwọn ̀wọn.

Èmi yóò kọ ̀yìn wọn, n yóò kọjú wọn

ọjọ́ àjálù wọn."

18 Wọ́n sọ , ", jẹ́ a lọ ṣọ̀tẹ̀ Jeremiah, nítorí òfin ìkọ́ni láti ẹnu àwọn àlùfáà yóò jásí asán, tàbí ìmọ̀ràn fún àwọn ọlọ́gbọ́n tàbí ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì. Nítorí náà , jẹ́ a kọlù ú pẹ̀ahọ́n wa, a ṣe tẹ́ohunkóhun ó sọ."

19 Dẹtí ̀rọ̀ mi Olúwa,

gbọ́ ohun àwọn ó fi sùn ń sọ.

20 Ṣe a fi rere san búburú?

Síbẹ̀ wọ́n ti gbẹ́ kòtò fún mi.

Rántí mo dúró níwájú rẹ,

mo sọ̀rọ̀ nítorí wọn,

láti ìbínú rẹ kúrò lọ́dọ̀ wọn.

21 Nítorí náà, jẹ́ ìyàn ọmọ wọn

jọ̀wọ́ wọn fún ọwọ́ idà

jẹ́ ìyàwó wọn ó di aláìlọ́mọ àti opó

jẹ́ a pa àwọn ọkùnrin wọn

a fi idà pa àwọn ̀dọ́mọkùnrin

wọn lójú ogun.

22 Jẹ́ a gbọ́ ohùn ẹkún láti ilé wọn

nígbà ó mu àwọn jagunjagun

kọlù wọ́n lójijì nítorí wọ́n ti gbẹ́

kòtò láti mi. Wọ́n ti dẹ okùn fún ẹsẹ̀ mi.

23 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa mọ

gbogbo ète wọn láti pa ,

ṣe dárí ̀bi wọn wọ́n

bẹ́̀ ni ṣe pa ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ kúrò lójú rẹ.

Jẹ́ wọn ó ṣubú níwájú rẹ,

bẹ́̀ ni ìwọ ó ṣe wọn nígbà ìbínú rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-