Publicidade

Ezequiel 1

̀alààyè àti ògo Olúwa

1 1.1: If 19.11. ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹrin mo di ọmọ ọgbọ̀n ọdún mo láàrín àwọn ìgbèkùn etí odò Kebari, àwọn ̀run ṣí sílẹ̀, mo ìran Ọlọ́run.

2 ọjọ́ karùn-ún oṣùó jẹ́ ọdún karùn-ún ìgbèkùn ọba Jehoiakini3 ni ̀rọ̀ Olúwa tọ àlùfáà Esekiẹli, ọmọ Busii , létí odò Kebari ni ilẹ̀ àwọn ará Babeli. Níbẹ̀ ni ọwọ́ Olúwa ti lára rẹ̀.

4 Mo , mo ìjì ń bọ̀ láti ìhà àríwá ìkùùkuu nípọn pẹ̀mọ̀nàmọ́ti n yẹ̀pẹ̀ìmọ́lẹ̀ rokoṣo i . Àárín iná náà ìgbà irin ń bẹ nínú iná, 5 1.5,18: If 4.6.àti láàrín iná náà ni ohun dàbí ̀alààyè mẹ́rin . Ìrísí wọn jẹ́ ti ènìyàn, 6 ṣùgbọ́n ẹnìkọ̀̀kan wọn ojú mẹ́rin àti ìyẹ́ apá mẹ́rin. 7 Ẹsẹ̀ wọn tọ́; àtẹ́lẹsẹ̀ wọn ti ọmọ màlúù, wọ́n tàn awọ idẹ dídán. 8 abẹ́ ìyẹ́ wọn ̀gbẹ́ mẹ́rẹ̀̀rin wọn ọwọ́ ènìyàn. Gbogbo àwọn mẹ́rẹ̀̀rin ojú àti àwọn ìyẹ́, 9 ìyẹ́ wọn kan ara wọn. Bẹ́̀ ̀kọ̀̀kan wọn padà lọ́ibi ó ń lọ; ṣùgbọ́n wọ́n ń lọ tààrà ni.

10 1.10: If 4.7. Báyìí ni ìrísí ojú àwọn ̀alààyè yìí: ̀kọ̀̀kan wọn ojú ènìyàn, apá ̀tún wọn, wọ́n ojú kìnnìún ìhà ̀tún, wọ́n ojú màlúù ìhà òsì, ̀kọ̀̀kan wọ́n tún ojú ẹyẹ idì. 11 Báyìí ni àpèjúwe ojú wọ́n. Ìyẹ́ wọn gbé sókè; ̀kọ̀̀kan wọn ìyẹ́ méjì, ìyẹ́ ̀kan kan ti èkejì ni ̀gbẹ̀̀gbẹ́, ìyẹ́ méjì tún bo ara wọn. 12 Olúkúlùkù wọn ń lọ tààrà. Níbikíbi èmi ń lọ, ni àwọn náà ń lọ, láì wẹ̀yìn wọ́n ti ń lọ. 13 Ìrísí àwọn ̀alààyè yìí dàbí ẹyin iná ń tàbí i iná fìtílà. Iná ń ń lọ sókè lọ sódò láàrín àwọn ̀alààyè; iná yìí mọ́lẹ̀ rokoṣo, ó ń yẹ̀yẹ̀jáde lára rẹ̀. 14 Àwọn ̀alààyè yìí ń sáré lọ sókè lọ sódò i ìtànṣán àrá.

15 1.15: If 4.5. mo ti ń wo àwọn ̀alààyè yìí, mo kẹ̀kẹ́ ilẹ̀ ni ̀gbẹ́ ̀kọ̀̀kan àwọn ̀alààyè wọ̀nyí pẹ̀ojú rẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin. 16 Àpèjúwe àti ìrísí àwọn kẹ̀kẹ́ náà nìyìí: kẹ̀kẹ́ mẹ́rẹ̀̀rin bákan náà, wọ́n ń tàn yinrin yinrin i kirisoleti, ̀kọ̀̀kan àwọn kẹ̀kẹ́ yìí i ìgbà a fi kẹ̀kẹ́ bọ kẹ̀kẹ́ nínú. 17 Àwọn kẹ̀kẹ́ yìí ń wọ́n ti ń , wọ́n ń lọ tààrà ibi ̀kọ̀̀kan àwọn ̀alààyè kọjú , kẹ̀kẹ́ wọn yapa àwọn ̀náà ti n lọ. 18 Àwọn ríìmù wọ́n ga, wọ́n ba ni lẹ́, àwọn ríìmù mẹ́rẹ̀̀rin jẹ́ kìkìdá ojú yíká.

19 àwọn ̀ń rìn, kẹ̀kẹ́ ̀gbẹ́ wọn náà yóò rìn, wọ́n sókè, kẹ̀kẹ́ náà yóò sókè. 20 Ibikíbi ̀ń lọ, kẹ̀kẹ́ wọn yóò wọn lọ, nítorí ̀àwọn ̀alààyè yìí nínú kẹ̀kẹ́ wọn. 21 àwọn ̀yìí ń lọ, kẹ̀kẹ́ náà yóò lọ; wọ́n dúró jẹ́́ kẹ̀kẹ́ náà yóò dúró jẹ́́, bẹ́̀ ni àwọn ̀yìí dìde nílẹ̀, àwọn kẹ̀kẹ́ yìí yóò dìde pẹ̀wọn, nítorí ̀̀alààyè wọ̀nyí nínú àwọn kẹ̀kẹ́.

22 Ohun ó dàbí òfúrufú ràn bo orí àwọn ̀alààyè wọ̀nyí, ó ń tàn yinrin yinrin i yìnyín, ó ba ni lẹ́. 23 Ìyẹ́ wọn tọ́ lábẹ́ òfúrufú, èkínní èkejì, ̀kọ̀̀kan wọn ìyẹ́ méjì méjì ó bo ara wọn. 24 1.24: El 43.2; If 1.15; 14.2; 19.6.Nígbà àwọn ̀náà gbéra, mo gbọ́ ariwo ìyẹ́ wọn bolẹ̀ i ríru omi, i ohùn Olódùmarè, i híhó àwọn jagunjagun. Nígbà wọ́n dúró jẹ́́, wọ́n rẹ ìyẹ́ wọn sílẹ̀.

25 wọ́n ṣe dúró wọ́n rẹ ìyẹ́ wọn sílẹ̀, ohùn kan jáde láti inú òfúrufú rán wọ́n. 26 1.26: If 1.13; 4.2.Lókè àwọ̀ òfúrufú borí wọn yìí ni ohun ó ìrísí ìtẹ́. Ìtẹ́ náà dàbí òkúta safire, lókè orí ìtẹ́ ohun dàbí ènìyàn . 27 Láti ibi ìbàdí ènìyàn náà òkè, o dàbí irin ń kọ yànrànyànràn. O dàbí pe kìkì iná ni, láti ibi ìbàdí rẹ ìsàlẹ̀ dàbí iná mọ́lẹ̀ i . 28 Ìmọ́lẹ̀ i yìí dàbí ìrísí òṣùmàrè yọ nínú àwọsánmọ̀ ọjọ́ òjò, bẹ́̀ ni ìmọ́lẹ̀ i .

Báyìí ni ìrísí ògo Olúwa. Nígbà mo i, mo dojúbolẹ̀, mo gbọ́ ohùn ẹnìkan ń sọ̀rọ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-