Publicidade

Jeremias 10

Ọlọ́run àti àwọn òrìṣà

1 Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa sọ fún yín ̀yin ilé Israẹli. 2 Báyìí ni Olúwa :

"ṣe kọ́ ìwà àwọn kèfèrí,

àmì ̀run ó dààmú yín,

nítorí wọ́n ń dààmú orílẹ̀-èdè.

3 Nítorí asán ni àṣà àwọn ènìyàn,

wọ́n igi láti inú igbó,

oníṣọ̀gbẹ́ pẹ̀àáké rẹ̀.

4 Wọ́n fi fàdákà àti wúrà ṣe é lọ́ṣọ̀́.

Wọ́n fi òòlù kàn án àti ìṣó

ó ba à ṣubú.

5 Wọ́n mọ́ igi ̀gúnsí inú oko,

òrìṣà wọn le è fọhùn.

Wọ́n gbọdọ̀ máa gbé

wọn nítorí wọn rìn.

ṣe bẹ̀wọn;

wọn le è ṣe ibi kankan

bẹ́̀ ni wọn si ṣe rere kan."

6 ẹni ó dàbí rẹ Olúwa;

o tóbi orúkọ rẹ tóbi lágbára.

7 Ta ni yẹ ó bẹ̀rẹ?

Ọba àwọn orílẹ̀-èdè?

Nítorí tìrẹ ni.

Láàrín àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn orílẹ̀-èdè

àti gbogbo ìjọba wọn,

ẹni ó dàbí rẹ.

8 Gbogbo wọn jẹ́ aláìlóye àti aṣiwèrè,

wọ́n ń kọ́ ̀kọ́ àwọn ère igi níláárí.

9 Fàdákà a ti kàn ni a láti Tarṣiṣi,

àti wúrà láti Upasi.

Èyí àwọn oníṣọ̀àti alágbẹ̀dẹ ṣe wọ́n

kùn àwọ̀ aró àti elése àlùkò,

èyí jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ àwọn ọlọ́gbọ́n oníṣọ̀.

10 Ṣùgbọ́n Olúwa ni Ọlọ́run tòótọ́,

òun ni Ọlọ́run alààyè, ọba ayérayé.

Nígbà ó bínú, ayé yóò wárìrì;

orílẹ̀-èdè fi ara da ìbínú rẹ̀.

11 "Sọ èyí fún wọn: Àwọn ọlọ́run kéékèèké ̀run àti ayé ni yóò ṣègbé láti ayé àti abẹ́ ̀run.’ "

12 Ọlọ́run ayé pẹ̀agbára rẹ̀,

ó àgbáyé pẹ̀ọgbọ́n rẹ̀,

ó ̀run ó fẹ̀ síta nípa òye rẹ̀.

13 Nígbà ó sán àrá, àwọn omi lọ́run a pariwo;

ó ìkùùkuu ru sókè láti òpin ayé.

Ó rán mọ̀nàmọ́pẹ̀òjò,

ó ń afẹ́fẹ́ láti ilé ìṣúra rẹ̀.

14 Gbogbo ènìyàn jẹ́ aṣiwèrè àti aláìnímọ̀,

ojú ti gbogbo alágbẹ̀dẹ níwájú ère rẹ̀,

nítorí ère dídá rẹ̀ èké ni,

ṣí ̀nínú rẹ̀.

15 Asán ni wọ́n, iṣẹ́ ìṣìnà;

nígbà ìbẹ̀wọn, wọn yóò ṣègbé.

16 Ẹni ó jẹ́ ìpín Jakọbu dàbí èyí,

nítorí òun ni ó ṣẹ̀ohun gbogbo

àti Israẹli ó jẹ́ ̀ìjogún rẹ̀.

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

Ìparun n bọ̀

17 ẹrù rẹ kúrò láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀

ìwọ o ń gbé ìlú a .

18 Nítorí èyí ni Olúwa :

"àkókò yìí, èmi yóò gbọn

àwọn ó ń gbé ilẹ̀ náà jáde.

Èmi yóò ìpọ́njú wọn,

wọn ó wọn ."

19 Ègbé ni fún mi nítorí ìpalára mi!

Ọgbẹ́ mi jẹ́ èyí sàn,

bẹ́̀ ni mọ sọ fún ara mi,

"Èyí ni àìsàn mi, mo gbọdọ̀ fi orí í."

20 Àgọ́ mi bàjẹ́,

gbogbo okùn rẹ̀ .

Àwọn ọmọ mi ti lọ lọ́dọ̀ mi, wọn mọ́,

ẹnìkankan yóò na àgọ́ mi mọ́,

tàbí yóò ṣe ibùgbé fún mi.

21 Àwọn olùṣọ́-àgùntàn jẹ́ aṣiwèrè,

wọn Olúwa:

nítorí náà wọn yóò ṣe rere

àti gbogbo agbo wọn ni yóò túká.

22 Fetísílẹ̀! ariwo igbe ń bọ̀,

àti ìdàrúdàpọ̀ ńlá láti ilẹ̀ àríwá !

Yóò sọ ìlú Juda di ahoro,

àti ihò ̀wàwà.

Àdúrà Jeremiah

23 Èmi mọ̀ Olúwa ̀ènìyàn í ṣe ti ara rẹ̀,

í ṣe fún ènìyàn láti tọ́ ìgbésẹ̀ ara rẹ̀.

24 Tún mi ṣe Olúwa, pẹ̀ìdájọ́ nìkan

o ṣe é nínú ìbínú rẹ,

ìwọ ṣe sọ di òfo.

25 ìbínú rẹ jáde sórí àwọn orílẹ̀-èdè

mọ̀ ́n,

sórí àwọn ènìyàn wọn pe orúkọ rẹ.

Nítorí wọ́n ti jẹ Jakọbu run,

wọ́n ti jẹ ́ run pátápátá,

wọ́n sọ ibùgbé rẹ̀ di ahoro.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-