5 23.5: Jr 33.15; Isa 4.2; Sk 3.8; 6.12. "Ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa wí,
"tí Èmi yóò gbé ẹ̀ka òdodo dìde fún Dafidi,
ọba tí yóò lo ìjọba pẹ̀lú ọgbọ́n
tí yóò sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.
5 23.5: Jr 33.15; Isa 4.2; Sk 3.8; 6.12. "Ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa wí,
"tí Èmi yóò gbé ẹ̀ka òdodo dìde fún Dafidi,
ọba tí yóò lo ìjọba pẹ̀lú ọgbọ́n
tí yóò sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.