Publicidade

Jeremias 29

Lẹ́si àwọn ìgbèkùn

1 Èyí ni ̀rọ̀ inú lẹ́wòlíì Jeremiah rán láti Jerusalẹmu ìyókù nínú àwọn àgbàgbà ó ìgbèkùn àti àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo àwọn ènìyàn Nebukadnessari ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ Babeli. 2 Lẹ́yìn ìgbà Jekoniah, ọba, àti ayaba, àti àwọn ìwẹ̀, àti àwọn ìjòyè Juda àti Jerusalẹmu, àwọn gbẹ́nàgbẹ́àti àwọn olùyàwòrán wọ́n lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu. 3 Ó fi lẹ́náà rán Eleasa ọmọ Ṣafani àti Gemariah ọmọ Hilkiah, ẹni Sedekiah ọba Juda rán Nebukadnessari ọba Babeli. .

4 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn mo lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu Babeli: 5 "kọ́ ilé máa gbé ibẹ̀, oko, máa jẹ èso ohun ̀gbìn oko yín. 6 ṣe ìgbéyàwó, ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin, gbé ìyàwó fún àwọn ọmọkùnrin yín, fi àwọn ọmọbìnrin yín fún ọkọ. àwọn náà ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. máa pọ̀ i iye, gbọdọ̀ dínkù iye níbẹ̀ rárá. 7 Bákan náà, máa àlàáfíà àti ìre ìlú, èyí mo yín lọ láti ṣe àtìpó. gbàdúrà Olúwa fún ìre ilẹ̀ náà; nítorí ó dára fún ilẹ̀ náà, yóò dára fún ̀yin pẹ̀." 8 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli : "ṣe gbà àwọn wòlíì èké àti àwọn aláfọ̀ṣẹ àárín yín tàn yín jẹ. ṣe fetísílẹ̀ àlá, èyí gbà wọ́n níyànjú láti . 9 Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún yín lórúkọ mi, Èmi rán wọn níṣẹ́," ni Olúwa .

10 Báyìí ni Olúwa : "Nígbà lo àádọ́rin ọdún Babeli, èmi yóò tọ̀ yín láti ṣe àmúṣẹ ìlérí ńlá mi fún un yín, àní láti o yín padà Jerusalẹmu. 11 Nítorí mo mọ èrò mo yín," ni Olúwa , "àní èrò àlàáfíà, í ṣe fún ibi, èrò láti fún un yín ìgbà ìkẹyìn àti ìrètí ọjọ́ iwájú. 12 Nígbà náà ni ̀yin yóò , ̀yin yóò gbàdúrà mi, èmi yóò gbọ́ àdúrà yín. 13 ̀yin yóò mi, ̀yin fi gbogbo ọkàn yín mi: ̀yin yóò mi ni Olúwa Ọlọ́run . 14 Èmi yóò di fún yín ni Olúwa , Èmi yóò yín padà kúrò ìgbèkùn. Èmi yóò ṣà yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè àti ibi gbogbo Èmi ti yín jáde, ni Olúwa . Èmi yóò yín padà ibi mo ti a yín ìgbèkùn lọ."

15 ̀yin , "Olúwa ti gbé àwọn wòlíì dìde fún wa Babeli." 16 Ṣùgbọ́n èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ti ọba ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi àti ti gbogbo ènìyàn ṣẹ́ìlú yìí; àní ti àwọn ènìyàn yín yín lọ ìgbèkùn, 17 bẹ́̀ ni, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn àárín wọn; Èmi yóò ṣe wọ́n èso ̀pọ̀tọ́ búburú ṣe é jẹ. 18 Èmi yóò fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn lépa wọn, Èmi yóò sọ wọ́n di ìríra lójú gbogbo ìjọba ayé, fún ègún, àti ìyanu, àti ̀sín, àti ̀gàn láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, ibi Èmi yóò wọn . 19 Nítorí wọ́n kọ̀ láti gbọ́ ̀rọ̀ mi," ni Olúwa Ọlọ́run . ̀rọ̀ mo tún ti ẹnu àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì sọ ̀yin ń ṣe àtìpó gbọ́ ni Olúwa Ọlọ́run .

20 Nítorí náà, gbogbo ̀yin ìgbèkùn, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, ̀yin mo rán lọ kúrò Jerusalẹmu lọ Babeli. 21 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli sọ nípa Ahabu ọmọ Kolaiah àti nípa Sedekiah ọmọ Maaseiah wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún un yín lórúkọ mi: "Èmi yóò fi wọ́n Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́. Òun yóò gba ̀wọn ìṣẹ́yìí gan an. 22 Nítorí tiwọn, ègún yìí yóò ran gbogbo àwọn àtìpó ilẹ̀ Babeli láti Juda: Olúwa yóò ṣe yín i Sedekiah àti Ahabu ọba Babeli dáná sun.23 Nítorí wọ́n ti ṣe ibi ilé Israẹli, wọ́n ti ṣe àgbèrè pẹ̀àwọn ìyàwó aládùúgbò wọn, àti orúkọ mi ni wọ́n ti ṣe èké, èyí Èmi rán wọn láti ṣe. Ṣùgbọ́n, Èmi mọ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jẹ́ ẹlẹ́rìí i," ni Olúwa .

Iṣẹ́ pàtàkì a rán Ṣemaiah

24 fún Ṣemaiah í ṣe Nehalami , 25 "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli : Ìwọ fi lẹ́ránṣẹ́ gbogbo àwọn ènìyàn Jerusalẹmu Sefaniah ọmọ Maaseiah í ṣe àlùfáà orúkọ mi; ó sọ fún Sefaniah , 26 Olúwa ti yàn ́ gẹ́gẹ́ àlùfáà rọ́Jehoiada láti máa jẹ́ alákòóso ilé Olúwa, o máa fi èyíkéyìí nínú àwọn aṣiwèrè ṣe i wòlíì si inú àgò irin. 27 Nítorí náà, èéṣe o fi Jeremiah ará Anatoti . Ẹni ó ń dúró i wòlíì láàrín yín? 28 Ó ti rán iṣẹ́ yìí wa ni Babeli , àtìpó náà yóò pẹ́ ó parí, nítorí náà, kọ́ ilé máa gbé ibẹ̀, oko, máa jẹ èso ohun ̀gbìn oko yín.’ "

29 Sefaniah àlùfáà ka lẹ́náà etí ìgbọ́ Jeremiah í ṣe wòlíì. 30 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah , 31 "Rán iṣẹ́ yìí gbogbo àwọn ìgbèkùn : Èyí ni ohun Olúwa ti Ṣemaiah, ará Nehalami: Nítorí Ṣemaiah ti sọtẹ́lẹ̀ fún un yín, ṣùgbọ́n èmi ran an, òun ń u yín gbẹ́kẹ̀èké. 32 Nítorí náà báyìí ni Olúwa : ó, èmi yóò bẹ Ṣemaiah, ará Nehalami , àti irú-ọmọ rẹ̀; òun yóò ọkùnrin kan láti máa gbé àárín ènìyàn yìí, bẹ́̀ ni yóò rere náà èmi yóò ṣe fún àwọn ènìyàn mi ni Olúwa , nítorí ó ti ti kéde ìṣọ̀tẹ̀ mi.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-