Publicidade

Jeremias 31

1 "Nígbà náà, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run fún gbogbo ìdílé ìran Israẹli, àwọn náà yóò jẹ́ ènìyàn mi," ni Olúwa .

2 Èyí ni ohun Olúwa :

"Àwọn ènìyàn ó àsálà lọ́wọ́ idà

yóò ojúrere Olúwa aṣálẹ̀,

Èmi yóò fi ìsinmi fún Israẹli."

3 Olúwa ti fi ara rẹ̀ hàn ìgbà kan , ó :

"Èmi ti nífẹ̀́ yín pẹ̀ìfẹ́ àìlópin;

mo ti fi ìfẹ́ ńlá yín,

4 Èmi yóò tún gbé e yín sókè,

àní a ó tún gbé e yín ìwọ wúńdíá ilẹ̀ Israẹli.

Àní ó tún tún ohun èlò orin yín gbé,

ó jáde síta pẹ̀ijó àti ayọ̀.

5 ó tún gbin ọgbà àjàrà

orí òkè Samaria;

àwọn àgbẹ̀ yóò máa

gbádùn èso oko wọn.

6 Ọjọ́ kan máa àwọn olùṣọ́ yóò kígbe jáde

lórí òkè Efraimu ,

, jẹ́ a gòkè lọ Sioni,

̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa.’ "

7 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa sọ :

"fi ayọ̀ kọrin Jakọbu;

olórí àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo.

Jẹ́ wọ́n gbọ́ ìyìn rẹ o ,

Olúwa, gba àwọn ènìyàn rẹ ;

àwọn ó ṣẹ́Israẹli.

8 ó, Èmi yóò wọn láti ilẹ̀ àríwá;

èmi yóò gbogbo wọn jọ láti òpin ayé.

Lára wọn ni yóò jẹ́ afọ́àti arọ,

aboyún àti obìnrin ń rọbí,

̀pọ̀ ènìyàn yóò .

9 Wọn yóò pẹ̀ẹkún,

wọn yóò gbàdúrà Èmi yóò ṣe wọn padà.

Èmi yóò jẹ́ atọ́fún wọn ̀odò omi;

̀ó tẹ́wọn yóò le ṣubú,

nítorí èmi ni baba Israẹli,

Efraimu ni àkọ́ọkùnrin mi.

10 "gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ̀yin orílẹ̀-èdè

kéde rẹ̀ erékùṣù jíjìn;

Ẹni ó Israẹli yóò kójọ,

yóò ṣọ́ agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn.

11 Nítorí Olúwa ti Jakọbu sílẹ̀, o á padà

ọwọ́ àwọn ó lágbára ú lọ.

12 Wọn yóò , wọn ó ìhó ayọ̀ lórí òkè Sioni;

wọn yóò yọ ayọ̀ níbi oore Olúwa.

Àlìkámà ni, ọtí wáìnì tuntun àti òróró

̀dọ́-àgùntàn àti ̀dọ́ ̀wọ́ ẹran.

Wọn ó dàbí ọgbà àjàrà a bomirin,

ìkorò wọn mọ́.

13 Àwọn wúńdíá yóò , wọn ó kún fún ayọ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ọkùnrin àti obìnrin.

Èmi yóò sọ ̀fọ̀ wọn di ayọ̀,

dípò ìkorò èmi yóò wọ́n nínú.

Èmi ó fún wọn ayọ̀.

14 Èmi ó tẹ́ àwọn àlùfáà lọ́rùn pẹ̀̀pọ̀;

àwọn ènìyàn mi yóò kún fún oore mi,"

ni Olúwa .

15 Èyí ni ohun Olúwa :

"A gbọ́ ohùn kan Rama

ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀ẹkún kíkorò.

Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀;

gbà wọ́n tu òun nínú,

nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ mọ́."

16 Báyìí ni Olúwa :

"ohùn rẹ dúró nínú ẹkún

àti ojú rẹ nínú omijé;

nítorí a ó fi èrè iṣẹ́ rẹ,"

ni Olúwa .

"Wọn ó padà láti ilẹ̀ ̀.

17 Nítorí ìrètí fún ọjọ́ iwájú rẹ,"

ni Olúwa .

"Àwọn ọmọ rẹ yóò padà ilẹ̀ wọn.

18 "Nítòótọ́, èmi ti gbọ́ ìpohùnréré Efraimu ,

Ìwọ ti mi gẹ́gẹ́ ọmọ màlúù a kọ́

èmi ti gbọ́ ìbáwí.

padà, èmi yóò yípadà,

nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run mi.

19 Lẹ́yìn èmi ti yípadà,

mo ronúpìwàdà,

lẹ́yìn èmi ti mọ̀,

èmi lu àyà mi.

Ojú , mo dààmú;

nítorí èmi gba èrè ̀gàn ìgbà èwe mi.

20 Efraimu í ha í ṣe ọmọkùnrin mi dáradára

inú mi dùn ?

èmi ti ń sọ̀rọ̀ i ,

síbẹ̀, èmi rántí rẹ̀.

Nítorí náà, ọkàn mi ṣe ohun kan fún un,

èmi káàánú gidigidi fún un,"

ni Olúwa .

21 "Gbé àmì ojú ̀dìde,

ṣe atọ́àmì,

kíyèsi òpópó ̀geere

ojú ̀ó ń gbà.

Yípadà ìwọ wúńdíá Israẹli,

padà àwọn ìlú rẹ.

22 Ìwọ yóò ti ṣìnà pẹ́ ,

ìwọ aláìṣòótọ́ ọmọbìnrin;

Olúwa yóò ohun tuntun lórí ilẹ̀,

ọmọbìnrin kan yóò ọkùnrin kan ."

23 Báyìí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Israẹli : "Nígbà èmi wọn láti ìgbèkùn; àwọn ènìyàn ó ilẹ̀ Juda àti àwọn ìlú rẹ̀ yóò tún lo àwọn ̀rọ̀ yìí lẹ́̀kan i; , Olúwa ó bùkún fún , ìwọ ibùgbé òdodo, ìwọ òkè ìwà mímọ́.’ 24 Àwọn ènìyàn yóò gbé papọ̀ Juda àti gbogbo àwọn ìlú rẹ̀; bákan náà ni àgbẹ̀ àti àwọn ń tẹ̀agbo ẹran wọn . 25 Èmi yóò sọ aláàárẹ̀ di ̀tun, èmi yóò tẹ́ gbogbo ọkàn ń káàánú lọ́rùn."

26 Lórí èyí ni mo , mo yíká, oorun mi dùn mọ́ mi.

27 "ó, ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa , "nígbà èmi yóò gbin ilé Israẹli àti ilé Juda pẹ̀irúgbìn ọmọ ènìyàn àti ẹranko. 28 Gẹ́gẹ́ mo ṣe ń ṣọ́ wọn, láti fàtu, àti láti lulẹ̀, àti láti gba ìṣàkóso, láti bàjẹ́ àti láti ibi , bẹ́̀ ni èmi yóò ṣọ́ wọn láti kọ́ àti láti gbìn," ni Olúwa . 29 "ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ènìyàn sọ mọ́ :

" Àwọn baba ti jẹ èso àjàrà àìpọ́n

àti eyín kan àwọn ọmọdé.

30 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ni yóò fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ẹnikẹ́ni ó jẹ èso kíkan ni eyín yóò kan.

31 "Ìgbà kan ń bọ̀," ni Olúwa ,

"Èmi yóò ilé Israẹli

àti ilé Juda májẹ̀tuntun.

32 dàbí májẹ̀

mo àwọn baba ńlá wọn ,

nígbà mo wọ́n lọ́wọ́,

mo wọn jáde Ejibiti

nítorí wọ́n da májẹ̀mi.

Lóòótọ́ ọkọ ni èmi jẹ́ fún wọn,"

ni Olúwa .

33 "Èyí ni májẹ̀èmi yóò ilé Israẹli

lẹ́yìn ìgbà náà," ni Olúwa :

"Èmi yóò fi òfin mi ọkàn wọn,

èmi ó kọ ́ àyà wọn.

Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn;

àwọn ó jẹ́ ènìyàn mi.

34 ọkùnrin kan ń kọ́ àwọn ará ilé rẹ̀

tàbí ọkùnrin ń kọ́ arákùnrin rẹ̀ , mọ Olúwa,

nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀

láti ẹni kékeré wọn títí ẹni ńlá,"

ni Olúwa .

"Nítorí èmi ó dárí àìṣedéédéé wọn ,

èmi rántí ̀ṣẹ̀ wọn mọ́."

35 Èyí ni ohun Olúwa :

ẹni ó oòrùn

tan ìmọ́lẹ̀ ̀sán,

ó òṣùpá àti ìràwọ̀

ràn òru;

ó omi Òkun sókè

bẹ́̀ ìjì rẹ̀ fi ń

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

36 "Àyàfi ìlànà yìí kúrò níwájú mi,"

ni Olúwa .

"Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Israẹli yóò dẹ́kun

láti jẹ́ orílẹ̀-èdè níwájú mi láéláé."

37 Èyí ni ohun Olúwa :

"Àyàfi a àwọn ̀run lókè

ìpìlẹ̀ ayé di àwárí ìsàlẹ̀,

ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli

nítorí ohun gbogbo wọ́n ti ṣe,"

ni Olúwa .

38 "Ọjọ́ náà ń bọ̀," ni Olúwa , "wọn yóò tún ìlú yìí kọ́ fún mi láti ilé ìṣọ́ Hananeli igun ẹnu ibodè. 39 Okùn ìwọ̀n yóò jáde láti ibi gígùn lọ òkè Garebu yóò lọ Goa. 40 Gbogbo àfonífojì níbi wọ́n ń da òkú àti eérú , àti gbogbo àfonífojì Kidironi ìhà ìlà-oòrùn títí igun ẹnu ibodè ẹṣin yóò jẹ́ mímọ́ Olúwa. A yóò fa ìlú náà tu tàbí a o palẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-