Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremias 9

1 Háà! Orí ìbá jẹ́ orísun omi

ojú mi jẹ́ orísun omijé!

Èmi yóò sọkún tọ̀sán tòru

nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.

2 Háà, èmi ìbá ni aginjù

ilé àgbàwọ̀ fún àwọn arìnrìn-àjò,

n ba à fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀

n lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn:

nítorí gbogbo wọn jẹ́ panṣágà

àjọ aláìṣòótọ́ ènìyàn.

3 Wọ́n ti pèsè ahọ́n wọn sílẹ̀

ọfà láti fi pa irọ́;

í ṣe nípa òtítọ́

ni wọ́n fi borí ilẹ̀ náà.

Wọ́n ń lọ láti inú ̀ṣẹ̀ kan òmíràn;

wọn náání mi,

Olúwa .

4 "Ṣọ́ra fún àwọn ̀rẹ́ rẹ;

ṣe gbẹ́kẹ̀àwọn arákùnrin rẹ.

Nítorí oníkálùkù arákùnrin jẹ́ atannijẹ,

oníkálùkù ̀rẹ́ jẹ́ abanijẹ́.

5 ̀rẹ́ ń dalẹ̀ ̀rẹ́. ṣí ẹni

sọ òtítọ́, wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn

láti máa purọ́. Wọ́n sọ ara wọn

di onírẹ̀wẹ̀pẹ̀̀ṣẹ̀

6 Ó ń gbé àárín ̀tàn;

wọ́n kọ̀ láti mọ̀ nínú ̀tàn wọn,"

ni Olúwa .

7 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun :

"ó, èmi dán wọn wo;

nítorí ni èmi tún le è ṣe?

Nítorí ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi?

8 Ahọ́n wọn dàbí ọfà olóró;

ó ń sọ ̀tàn.

Oníkálùkù ń fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ àlàáfíà aládùúgbò rẹ̀,

inú ọkàn rẹ̀, ó dẹ tàkúté sílẹ̀.

9 Èmi yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n nítorí èyí?"

ni Olúwa .

"Èmi yóò ha gbẹ̀san ara

mi lórí irú orílẹ̀-èdè yìí ?"

10 Èmi yóò sọkún, pohùnréré ẹkún fún àwọn òkè

àti ẹkún ìrora lórí pápá oko aginjù wọ̀n-ọn-nì.

Nítorí wọ́n di ahoro, wọn kọjá ibẹ̀.

A gbọ́ igbe ẹran ̀sìn.

Àwọn ẹyẹ ojú ̀run ti sálọ,

bẹ́̀ náà ni àwọn ẹranko ti lọ.

11 "Èmi yóò sọ Jerusalẹmu di òkìtì

àlàpà àti ihò àwọn ìkookò.

Èmi ó sọ ìlú Juda di ahoro

ẹnikẹ́ni le è gbé."

12 Ta ni ẹni náà ó ọgbọ́n láti mòye nǹkan wọ̀nyí? Ta ni Olúwa ti sọ èyí fún, ó ṣàlàyé rẹ̀? Èéṣe ilẹ̀ náà fi ṣègbé aginjù, ẹnìkankan le á kọjá?

13 Olúwa , nítorí wọ́n ti kọ òfin mi sílẹ̀, èyí mo gbé kalẹ̀ níwájú wọn, wọn ṣe àìgbọ́ràn wọn, wọn rìn nínú òfin mi. 14 Dípò èyí, wọ́n ti tẹ̀agídí ọkàn wọn, wọ́n ti tẹ̀Baali gẹ́gẹ́ àwọn baba wọn ṣe kọ́ wọn. 15 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli , "ó, Èmi yóò àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ oúnjẹ kíkorò àti láti mu omi májèlé. 16 Èmi yóò wọn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, nínú èyí àwọn tàbí àwọn baba wọn mọ̀. Èmi yóò lépa wọn pẹ̀idà títí èmi yóò fi pa wọ́n run."

17 Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun :

"à ó nísinsin yìí! obìnrin ti ń ṣọ̀fọ̀ ó ;

ránṣẹ́ pe àwọn ó mòye nínú wọn.

18 Jẹ́ wọn kíákíá,

wọn pohùnréré ẹkún

wa lórí títí ojú wa yóò

fi sàn fún omijé omi yóò máa sàn àwọn ìpéǹpéjú wa.

19 A gbọ́ igbe ìpohùnréré

ẹkún Sioni:

Àwa ti ṣègbé !

A gbọdọ̀ fi ilẹ̀ wa sílẹ̀,

nítorí àwọn ilé wa ti parun.’ "

20 Nísinsin yìí, ̀yin obìnrin gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa;

ṣí etí yín ̀rọ̀ ẹnu rẹ.

Kọ́ àwọn ọmọbìnrin yín ìpohùnréré ẹkún,

kọ́ ara yín arò.

21 Ikú ti gba ojú fèrèsé wa wọlé

ó ti wọ odi alágbára wa

ó ti àwọn ọmọ kúrò àdúgbò

àti àwọn ̀dọ́mọkùnrin kúrò gbọ̀ngàn ìta gbangba.

22 Sọ , "Èyí ni ohun Olúwa :

" Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubú

ààtàn oko gbangba

àti ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórè

láìsí ẹnìkankan láti wọn jọ.’ "

23 Èyí ni ohun Olúwa :

"ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n yangàn nítorí agbára ọgbọ́n rẹ̀,

tàbí alágbára nítorí agbára rẹ̀,

tàbí ọlọ́rọ̀ nítorí ọrọ̀ rẹ̀.

24 9.24: 1Kọ 1.31; 2Kọ 10.17. jẹ́ ẹni ń ṣògo nípa èyí :

òun òye, òun mọ̀ ,

Èmi ni Olúwa ń ṣe òtítọ́,

ìdájọ́ àti òdodo ayé,

nínú èyí ni mo inú dídùn ,"

Olúwa .

25 "Ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa , "Èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn a kọ ilà fún nínú ara nìkan. 26 Ejibiti, Juda, Edomu, Ammoni, Moabu àti gbogbo àwọn ń gbé ̀jíjìn réré aginjù. Nítorí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jẹ́ aláìkọlà gbogbo àwọn ará ilé Israẹli jẹ́ aláìkọlà ọkàn."

Veja também